Ẹ̀bùnólúwa Adéjúyìgbé
Ìrísí
Ebunoluwa Aderonke Adejuyigbe jẹ́ onímọ̀ nípa àwọn ọmọdé, olùwádìí, àti olùdarí ẹ̀kọ́ ní Nàìjíríà. Ó jẹ́ Ọ̀jọ̀gbọ́n nínú ìmọ̀ nípa àwọn ọmọdé àti ìlera ọmọdé, láti oṣù Agẹmọ ọdún 2025, òun sì ni Ọ̀gá Àgbà fún Ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti onímọ̀ ìṣègùn Sáyẹ́nsì (UNIMED), ní ìpínlè Òǹdó. Òun ni obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ́ ọ̀gá Àgbà ní ilé ẹ̀kọ́ gíga náà. [1] [2]
- ↑ "Challenges won't stop us from setting standards—UNIMED VC". 28 July 2025. https://punchng.com/challenges-wont-stop-us-from-setting-standards-unimed-vc/.
- ↑ "Adejuyigbe assumes role as UNIMED's first female VC". 23 July 2025. https://guardian.ng/education/adejuyigbe-assumes-role-as-unimeds-first-female-vc/.