Aajiirebi
| Aajiirebi | |
|---|---|
The 3 presenters of the TV show in a group photo at the studio | |
| Genre | Talk show |
| Created by | Africa Magic |
| Presented by | Damilola Oni Bamidele Fagboyo Feyikemi Agbola |
| Country of origin | Nigeria |
| Original language(s) | Yoruba |
| No. of seasons | 13 |
| No. of episodes | 301 |
| Production | |
| Producer(s) | Leye Fabusoro |
| Production location(s) | Ibadan |
| Running time | 30 minutes |
| Release | |
| Original network | Africa Magic Yoruba |
| Original release | 2014 – present |
Aajiirebi jẹ ère àgbéléwò ní orílè-èdè Nàìjíríà èyítí Damilola Oni àti Bamidele Fagboyo mon dárí rẹ ní orí ẹ̀rọ mọhn mú àwòrán tí DSTV àti GOtv ní èdè abínibí yorùbá.[1] Won bẹrẹ ètò náà ní orí afẹ́fẹ́ ní ọdún 2014 ni èyítí wọn tí ṣe mẹ́tàlá irú ère náà lórí afẹ́fẹ́.[2] Aajiirebi jẹ ètò èyítí wọn tí yà àwòrán rẹ kalẹ síwájú àkókò ère náà lórí mohunmaworan fún ọgbọ́n ìṣẹ́jú ère èyítí ohùn kò ní ní ọgbọ́n àti ìdárayá ní èyítí wọn mọ ṣe ní ìkan ní Africa Magic Yorùbá pẹ̀lú àfojúsùn èyítí o dá lé lórí ọ̀rọ̀ àwùjọ àti àṣà Yorùbá lọwọlọwọ ní orílè-èdè Nàìjíríà àti àwùjo adúláwò èyítí Tunde Oladimeji mon dárí rẹ tí Leye Fabusoro sì jẹ Olùpèsè ère àgbéléwò náà.[3][4] Ère itage náà pín sí abala orisirisi bí abala ifiorowanilenuwo àti abala Anike Kilonsele èyítí Feyikemi Agbola mon ṣe alábòójútó rẹ nibiti wọn tí ṣe idanilekoo lórí ohùn ton ṣẹlẹ̀ láwùjọ lọwọlọwọ láti fí ṣe ari kò gbọ́n nípa isẹmi ayé wà ní ojo jù mó.[5]
Itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Yoruba TV show kicks off new season with new female host". Pulse Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2017-10-01. Retrieved 2020-08-13.
- ↑ "Africa Magic Yoruba". Africa Magic - Africa Magic Yoruba (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-08-13.
- ↑ "Rare Edge media targets global partnership for Aajirebi". Tribune Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2017-09-29. Retrieved 2020-08-13.
- ↑ Admin. "Aajiirebi breakfast TV show ready with a new season". 1st website. Retrieved 13 August 2020.
- ↑ "Aajiirebi enters new season, gets new presenter". Latest Nigeria News, Nigerian Newspapers, Politics (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2017-09-24. Retrieved 2020-08-13.