Abdulkareem Jubreel Ayodeji
Abdulkareem Jubreel Ayodeji | |
|---|---|
| Member of the Lagos State House of Assembly | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
| Ó gun orí àga 18 March 2023 | |
| Member of the Lagos State House of Assembly from Agege Local Government | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
| Ó gun orí àga 18 March 2023 | |
| Constituency | Agege |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | 15 Oṣù Kẹrin 1960 Agege, Agege Local Government Lagos State Nigeria |
| Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressive Congress |
| Education | Lagos State University Olabisi Onabanjo University |
| Alma mater | |
| Occupation |
|
Abdulkareem Jubreel Ayodeji je olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà to n sójú àgbègbè Agege Constituency II, ni ìjọba ìbílẹ̀ Agege ni ile ìgbìmọ̀ asofin Ìpínlẹ̀ Eko.[1][2][3]
Igbesi aye ibẹrẹ ati ẹkọ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]A bi Abdulkareem ni odún 1960 ni ìjọba ìbílè Agege ni Ìpínlè Eko, Nigeria . Ni ọdún 2008 o kàwé gbà ìwé ẹ̀rí degree rẹ ni pa ètò ẹ̀kọ́ Cooperatives & Business Management láti ilé ìwé gíga Yunifásítì Olabisi Onabanjo University ti o wà ní Ago Iwoye o sí tún tẹsiwaju nípa ètò ẹ̀kọ́ rẹ láti kàwé gbà ìwé ẹ̀rí Master rẹ ni ìṣàkóso ètò Ìjọba láti ilé ìwé gíga Yunifásítì Lagos State University (LASU) ni ọdún 2014.[3]
Iṣẹ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Abdulkareem jẹ alákòóso ti o ti ṣiṣẹ tẹlẹ gẹgẹbi alábòójútó fun ìlera àgbègbè Agege ni Ìpínlè Eko ṣáájú ìdìbò rẹ gẹ́gẹ́bíi ọmọ ilé igbimọ aṣòfin kẹwàá ni Ìpínlẹ̀ Eko ni ọdún 2023 labẹ ẹgbẹ òṣèlú All Progressive Congress nínú ètò idibo gbogboogbo ni ọdún 2023.[3]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "ShineYourEye". www.shineyoureye.org. Retrieved 2025-12-03.
- ↑ "LeaderBox - Political Leadership Platform". leaderbox.africa (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-12-03.
- 1 2 3 "Countdown to 2019: Profile of 'Jubi', the Accord Party candidate for Agege Constituency 1" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-12-03.