Jump to content

Abdulkareem Jubreel Ayodeji

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Abdulkareem Jubreel Ayodeji
Member of the Lagos State House of Assembly
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
18 March 2023
Member of the Lagos State House of Assembly
from Agege Local Government
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
18 March 2023
ConstituencyAgege
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí15 Oṣù Kẹrin 1960 (1960-04-15) (ọmọ ọdún 65)
Agege, Agege Local Government Lagos State Nigeria
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressive Congress
EducationLagos State University Olabisi Onabanjo University
Alma mater
Occupation
  • Politician
  • Administrator

Abdulkareem Jubreel Ayodeji je olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà to n sójú àgbègbè Agege Constituency II, ni ìjọba ìbílẹ̀ Agege ni ile ìgbìmọ̀ asofin Ìpínlẹ̀ Eko.[1][2][3]

Igbesi aye ibẹrẹ ati ẹkọ

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bi Abdulkareem ni odún 1960 ni ìjọba ìbílè Agege ni Ìpínlè Eko, Nigeria . Ni ọdún 2008 o kàwé gbà ìwé ẹ̀rí degree rẹ ni pa ètò ẹ̀kọ́ Cooperatives & Business Management láti ilé ìwé gíga Yunifásítì Olabisi Onabanjo University ti o wà ní Ago Iwoye o sí tún tẹsiwaju nípa ètò ẹ̀kọ́ rẹ láti kàwé gbà ìwé ẹ̀rí Master rẹ ni ìṣàkóso ètò Ìjọba láti ilé ìwé gíga Yunifásítì Lagos State University (LASU) ni ọdún 2014.[3]

Abdulkareem jẹ alákòóso ti o ti ṣiṣẹ tẹlẹ gẹgẹbi alábòójútó fun ìlera àgbègbè Agege ni Ìpínlè Eko ṣáájú ìdìbò rẹ gẹ́gẹ́bíi ọmọ ilé igbimọ aṣòfin kẹwàá ni Ìpínlẹ̀ Eko ni ọdún 2023 labẹ ẹgbẹ òṣèlú All Progressive Congress nínú ètò idibo gbogboogbo ni ọdún 2023.[3]

  1. "ShineYourEye". www.shineyoureye.org. Retrieved 2025-12-03.
  2. "LeaderBox - Political Leadership Platform". leaderbox.africa (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-12-03.
  3. 1 2 3 "Countdown to 2019: Profile of 'Jubi', the Accord Party candidate for Agege Constituency 1" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-12-03.