Jump to content

Abubakar Hassan Fulata

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Abubakar Hassan Fulata jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà. o sìn gẹ́gẹ́bíi ọmọ ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú àgbègbè Birniwa/Guri/Kirikasamma ni ilé ìgbìmò aṣòfin àgbà. Wọn bí ní ọjọ́ kẹta oṣù kẹta ọdún 1959, o jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Jigawa o ni iwe-ẹri bachelor láti ilé ìwé gíga Yunifásítì. Wọ kọ́kọ́ diboyan yàn sì ilé igbimọ aṣòfin àgbà nínú ìdíje ìdìbò gbogbo gbo ọdún 2015. Wọn tún yàn ni ọdún 2019, wọ́n tún dibo yàn fún ìgbà kẹta ni ọdun 2023 lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC).[1][2][3]

  1. "10th National Assembly Members - Voter - Validating the Office of the Electorate on Representation". orderpaper.ng. Retrieved 2025-01-06.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  2. "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-06.
  3. "National Assembly | Federal Republic of Nigeria". nass.gov.ng. Retrieved 2025-01-06.