Abubakar Yabo Umaru
Ìrísí
Abubakar Yabo Umaru je olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Naijiria ati aṣofin ti a bi ni ọdún 1971 ni Ìpínlẹ̀ Sokoto, Nigeria . Ni 2019, o jẹ ọmọ ẹgbẹ ti Ile-igbimọ Aṣoju ti Ìpínlẹ̀ Sokoto, ti o nsójú àgbègbè Shagari/Yabo.[1][2]
Ji jawe olú borí re nínú ètò ìdìbò ọdún 2023 ni alátakò rẹ gbé lọ sí ilé ẹjọ tí o sì pàdánù ẹjọ náà sì ọwọ Umar Yusuf Yabo tí ọmọ ẹgbẹ òṣèlú Peoples Democratic Party (PDP) )lẹ́yìn ìdájọ́ ilé ẹjọ.[3]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2024-12-13.
- ↑ Content-man (2019-09-05). "Sokoto Tribunal dismisses petitions against Abubakar Yabo, Tukur Bodinga". News Diary Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2024-12-13.
- ↑ Jeremiah, Urowayino (2024-08-24). "Appeal Court affirms Umar Yusuf Yabo, as Reps member". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-08.