Jump to content

Adesewa Josh

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Adesewa Josh
Ọjọ́ìbíAdesewa Hannah Ogunleyimu
11 Oṣù Kẹ̀wá 1985 (1985-10-11) (ọmọ ọdún 39)
Ipetu-Ijesha, Osun State, Nigeria
Ẹ̀kọ́Lagos State University
Columbia University Graduate School of Journalism
Iṣẹ́Broadcast journalist
Ìgbà iṣẹ́2012–present
Awards2017: The Future Awards Africa,

Adesewa Hannah Ogunleyimu , tí wọ́n bí ní ọjọ kọkànlá oṣù kẹwa , ọdún 1985. Adesewa Josh, jẹ akoroyin orilẹ - èdè Nàìjíríà tí ó n kọ iroyin tilé toko fúnTRT World. [1] Nigba kan ri, ó jé oṣiṣẹ ni ilé-isẹ́ telifisan Channels TV lati ọdún 2012 sí ọdún 2017.[2]

Ìbẹ̀rẹ̀ ayé rẹ àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Josh ní wọn bí ní àdúgbò Ipetu-Ijesha ní ìlúOsun State ní apá ìwọòrùn Nàìjíríà sí ilé Josiah Ogunleyimu, bàbá rẹ,tí ó wá láti ìlú Osun ní orilẹ-ede Nàìjíríà àti Abimbola Ogunleyimu, ìyá rẹ tí ó wá láti agbègbè Epe, ni ilú Èkó.

Ní ọdún 2009, Josh gbà a ìwé èrí nínú igberoyin jáde àti ìjábọ̀ lọ́wọ́ BBC World Service.[2] Ní ọdún 2010, ó gba iwe-eri nínú ìjọba lọwọ ilé-isẹ́ Alder ati ni ọdún 2012, o tun gba iweeri nínú ìmọ bí a se n gbe eto jade lori ẹrọ amóunmáwòrán ni UK's Aspire Presenting Institute.[2] Ó tún ní iwe-eri nínú ìfáàrà ètò ìroyin lọwọ Redio Nàìjíríà.[3]

Ní ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ọdún 1990, Josh sisẹ́ gẹgẹ bi osere ọmọde l'orilẹ ede Nàìjíríà , níbi tí o ti jẹyọ ní ABC Wonderland from Galaxy Television. O tun ṣiṣẹ lórí ọsẹ ti orukọ rẹ n jẹTinsel. Josh tun jẹyọ ní University of Ibadan Theater Art Hall fun ìgbéjáde tíátà níbí tí o ti jẹyọ ninu Wedlock of the Gods, The Gods are Not to Blame, àti Under the Moon.

Ni ọdun 2007, Josh wà lára àwọn ẹgbẹ amóunmáwòrán orilẹ-ede Nàìjíríà tí wón se ètò tí wón pe ní Next Movie Star, tí o da lórí ṣíṣe àwárí awọn tí o ni ẹ̀bùn nínú eré ṣíṣe.

Ní ọdún 2012, Josh ṣe ètò amóunmáwòrán kan ti a pè nì Lucozade Boost Freestyle pẹlu Julius Agwu. O tun jẹyọ gẹgẹ bí adajọ lórí Nigerian Idol.

Ni oṣu keje ọdún 2012, Josh bẹrẹ iṣẹ rẹ gẹgẹ bi akọroyin gẹgẹ bi igbakeji ètò arọ ti a mọ sì Sunrise Daily lórí Nigerian cable news network Channels TVLagos, Nigeria. O di akaroyin irọlẹ fún Channels TV ti o si ṣiṣe gẹgẹ bí ajabọ ìròyìn ti ṣi gba ipo di ọdún 2017.[2][4]

Àwọn àmì-ẹ̀yẹ rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  • 2016: CHAMP Xceptional Women Network, Xceptional Women in Media Award[5][6]
  • 2017: The Future Awards Africa, The Future Awards Prize for On-Air Personality (Visual), Nominee[7]

Àwọn ẹgbẹ́ tó darapọ̀ mọ́

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "Adesewa Josh" (video). Media Hang Out Nigeria. August 9, 2016. https://www.youtube.com/watch?v=-Szirka0_6Y. 
  2. 2.0 2.1 2.2 2.3 Okon, Austin (January 9, 2017). "Adesewa Josh". Lagos, Nigeria: Channels TV. Archived from the original on August 16, 2018. https://web.archive.org/web/20180816061657/https://www.channelstv.com/adesewa-josh/. Retrieved August 12, 2018. 
  3. Bello, Ono (November 27, 2017). "Award Winning Broadcast Journalist, Adesewa Josh, Graduates Top Female Black Student From Columbia University". OnoBello. Archived from the original on November 20, 2021. https://web.archive.org/web/20211120165351/https://onobello.com/award-winning-broadcast-journalist-adesewa-josh-graduates-top-female-black-student-from-columbia-university/. 
  4. Filani, Kemi (January 9, 2016). "Stop comparing and start owing your own: Channels TV presenter, Adesewa Josh reacts as Mark Zuckerberg jogs in Lagos without a body guard". Kemi Filani News (Lagos, Nigeria). https://www.kemifilani.ng/2016/09/stop-comparing-and-start-owing-your-own.html. 
  5. Essiet, Daniel (July 12, 2016). "NGO takes women empowerment centre stage". The Nation. https://thenationonlineng.net/ngo-takes-women-empowerment-centre-stage/. 
  6. Utor, Florence (July 3, 2016). "Salami lifts women with xceptional women network". The Guardian (Lagos, Nigeria). https://guardian.ng/sunday-magazine/salami-lifts-women-with-xceptional-women-network/. 
  7. Okocha, John (November 24, 2017). "The Future Awards Africa 2017: Wizkid, Davido up for awards". The Nation. https://thenationonlineng.net/the-future-awards-africa-2017-wizkid-davido-up-for-awards/.