Adesewa Josh
Adesewa Josh | |
---|---|
Ọjọ́ìbí | Adesewa Hannah Ogunleyimu 11 Oṣù Kẹ̀wá 1985 Ipetu-Ijesha, Osun State, Nigeria |
Ẹ̀kọ́ | Lagos State University Columbia University Graduate School of Journalism |
Iṣẹ́ | Broadcast journalist |
Ìgbà iṣẹ́ | 2012–present |
Awards | 2017: The Future Awards Africa, |
Adesewa Hannah Ogunleyimu , tí wọ́n bí ní ọjọ kọkànlá oṣù kẹwa , ọdún 1985. Adesewa Josh, jẹ akoroyin orilẹ - èdè Nàìjíríà tí ó n kọ iroyin tilé toko fúnTRT World. [1] Nigba kan ri, ó jé oṣiṣẹ ni ilé-isẹ́ telifisan Channels TV lati ọdún 2012 sí ọdún 2017.[2]
Ìbẹ̀rẹ̀ ayé rẹ àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Josh ní wọn bí ní àdúgbò Ipetu-Ijesha ní ìlúOsun State ní apá ìwọòrùn Nàìjíríà sí ilé Josiah Ogunleyimu, bàbá rẹ,tí ó wá láti ìlú Osun ní orilẹ-ede Nàìjíríà àti Abimbola Ogunleyimu, ìyá rẹ tí ó wá láti agbègbè Epe, ni ilú Èkó.
Ní ọdún 2009, Josh gbà a ìwé èrí nínú igberoyin jáde àti ìjábọ̀ lọ́wọ́ BBC World Service.[2] Ní ọdún 2010, ó gba iwe-eri nínú ìjọba lọwọ ilé-isẹ́ Alder ati ni ọdún 2012, o tun gba iweeri nínú ìmọ bí a se n gbe eto jade lori ẹrọ amóunmáwòrán ni UK's Aspire Presenting Institute.[2] Ó tún ní iwe-eri nínú ìfáàrà ètò ìroyin lọwọ Redio Nàìjíríà.[3]
Isẹ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ní ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ọdún 1990, Josh sisẹ́ gẹgẹ bi osere ọmọde l'orilẹ ede Nàìjíríà , níbi tí o ti jẹyọ ní ABC Wonderland from Galaxy Television. O tun ṣiṣẹ lórí ọsẹ ti orukọ rẹ n jẹTinsel. Josh tun jẹyọ ní University of Ibadan Theater Art Hall fun ìgbéjáde tíátà níbí tí o ti jẹyọ ninu Wedlock of the Gods, The Gods are Not to Blame, àti Under the Moon.
Ni ọdun 2007, Josh wà lára àwọn ẹgbẹ amóunmáwòrán orilẹ-ede Nàìjíríà tí wón se ètò tí wón pe ní Next Movie Star, tí o da lórí ṣíṣe àwárí awọn tí o ni ẹ̀bùn nínú eré ṣíṣe.
Ní ọdún 2012, Josh ṣe ètò amóunmáwòrán kan ti a pè nì Lucozade Boost Freestyle pẹlu Julius Agwu. O tun jẹyọ gẹgẹ bí adajọ lórí Nigerian Idol.
Ni oṣu keje ọdún 2012, Josh bẹrẹ iṣẹ rẹ gẹgẹ bi akọroyin gẹgẹ bi igbakeji ètò arọ ti a mọ sì Sunrise Daily lórí Nigerian cable news network Channels TV ní Lagos, Nigeria. O di akaroyin irọlẹ fún Channels TV ti o si ṣiṣe gẹgẹ bí ajabọ ìròyìn ti ṣi gba ipo di ọdún 2017.[2][4]
Àwọn àmì-ẹ̀yẹ rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- 2016: CHAMP Xceptional Women Network, Xceptional Women in Media Award[5][6]
- 2017: The Future Awards Africa, The Future Awards Prize for On-Air Personality (Visual), Nominee[7]
Àwọn ẹgbẹ́ tó darapọ̀ mọ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- 2016: Junior Achievement Nigeria
- 2016: Nigerian Leadership Initiative, Associate Fellow
- Young African Leaders Initiative, YALI Network Member
- Global Investigative Journalism Network (GIJ)
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Adesewa Josh" (video). Media Hang Out Nigeria. August 9, 2016. https://www.youtube.com/watch?v=-Szirka0_6Y.
- ↑ 2.0 2.1 2.2 2.3 Okon, Austin (January 9, 2017). "Adesewa Josh". Lagos, Nigeria: Channels TV. Archived from the original on August 16, 2018. https://web.archive.org/web/20180816061657/https://www.channelstv.com/adesewa-josh/. Retrieved August 12, 2018.
- ↑ Bello, Ono (November 27, 2017). "Award Winning Broadcast Journalist, Adesewa Josh, Graduates Top Female Black Student From Columbia University". OnoBello. Archived from the original on November 20, 2021. https://web.archive.org/web/20211120165351/https://onobello.com/award-winning-broadcast-journalist-adesewa-josh-graduates-top-female-black-student-from-columbia-university/.
- ↑ Filani, Kemi (January 9, 2016). "Stop comparing and start owing your own: Channels TV presenter, Adesewa Josh reacts as Mark Zuckerberg jogs in Lagos without a body guard". Kemi Filani News (Lagos, Nigeria). https://www.kemifilani.ng/2016/09/stop-comparing-and-start-owing-your-own.html.
- ↑ Essiet, Daniel (July 12, 2016). "NGO takes women empowerment centre stage". The Nation. https://thenationonlineng.net/ngo-takes-women-empowerment-centre-stage/.
- ↑ Utor, Florence (July 3, 2016). "Salami lifts women with xceptional women network". The Guardian (Lagos, Nigeria). https://guardian.ng/sunday-magazine/salami-lifts-women-with-xceptional-women-network/.
- ↑ Okocha, John (November 24, 2017). "The Future Awards Africa 2017: Wizkid, Davido up for awards". The Nation. https://thenationonlineng.net/the-future-awards-africa-2017-wizkid-davido-up-for-awards/.