Adetoun Olabowale Bailey
Adetoun Olabowale Bailey, née Odufunade jẹ òní ìmò agbẹ̀bí àti olùṣàkóso fún àwọn agbẹ̀bí.[1]
Ìgbésí àyè
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Bailey lọ kọ ẹkọ ní ìlú Lọndọnu gẹ́gẹ́bíi orthopaedic nurse àti òní ìmò iṣẹgun nípa ìṣe agbẹ̀bí midwife.[2] She qualified as a nurse in 1951,[3] Ni ibẹrẹ ọdún 1950s o ṣiṣẹ gẹgẹbi agbẹ̀bí, akeeko nípa ìṣe agbẹ̀bí and nursing sister in the UK and Nigeria. Láàrin ọdún 1956 sì ọdún 1958 ó jé olùdarí àti alákòóso fún ọgbà ilé ìwòsàn àti teaching sister at General Hospital, Limbe, Cameroon. From 1958 to 1961 she was operating theatre sister at General Hospital, Lagos.[1] Bailey je akọ̀wé ẹgbẹ agbẹ̀bí ti Midwives Board of Nigeria láàrin ọdún 1962 sì ọdún 1972 àti akọ̀wé ẹgbẹ Nursing Council of Nigeria láàrin ọdún 1972 sì ọdún 1977.[1] Nígbàtí ẹgbẹ́ méjèèjì darapọ si eyokan ti wón n pè ni Nursing and Midwifery Council of Nigeria ni ọdún 1979, o ṣiṣẹ gẹgẹbi Obìnrin àkọ́kọ́ gẹ́gẹ́bíi akowe àgbà.[4] O jẹ alábòójútó fún isayewo títẹ́ àwọn ìwé náà èyítí o da lè lórí tropical nursing àti health sciences tí ilé ìṣe itewe Macmillan se àgbéjáde rẹ láàrin ọdún 1974 sókè,[1] tí o sì pà wo po kọ ọpọlọpọ àkòrí ìwé nínú ìwé náà. Ni ọdún 1981 ó sìn gẹ́gẹ́bíi aree ẹgbẹ Obìnrin la àgbáyé International Women's Society, ní orílè-èdè Nàìjíríà.[5]
Awọn iṣẹ rẹ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- (with C. K. O. Uddoh) Nutrition. Macmillan Education, 1980. ISBN 978-0333284377
- (with Victoria A. Ajayi) Textbook of Midwifery. Macmillan Education, 1980. ISBN 978-0333275849
- (with Anu Adegoroye) Community Health Care. Macmillan Education, 1984. ISBN 978-0333286234
Itọkasi=
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- 1 2 3 4 Elizabeth Sleeman (2001). "BAILEY, Adetoun Olabowale". The International Who's Who of Women 2002. Psychology Press. pp. 36–7. ISBN 978-1-85743-122-3. https://books.google.com/books?id=6J8xDWDqOkEC&pg=PA36.
- ↑ Albert Aduloju Agbaje (2001). Abiodun Lagos, a Blossomy Tree in the Desert: A Biography of Joseph Abiodun Adetiloye. CSS Limited. p. 102. ISBN 978-978-2951-73-1. https://books.google.com/books?id=oECgAAAAMAAJ.
- ↑ Registration of Nurses, Federal Republic of Nigeria Official Gazette, Vol. 56, No 6 (1st February 1969)
- ↑ M. Elizabeth Carnegie (1999). The Path We Tread: Blacks in Nursing Worldwide, 1854-1994. Jones & Bartlett Learning, LLC. p. 267. ISBN 978-0-7637-1247-1. https://books.google.com/books?id=ZVQ4AQAAIAAJ.
- ↑ Past Presidents Archived 2021-08-17 at the Wayback Machine., International Women's Society, Nigeria. Accessed 17 January 2021.