Adeyinka Oyekan
| Oba Adeyinka Oyekan II | |
|---|---|
| Oba of Lagos | |
| Reign | 1965–2003 |
| Coronation | 1965 |
| Predecessor | Adeniji Adele |
| Successor | Rilwan Akiolu |
| House | Ologun Kutere |
| Father | Prince Kusanu Abiola Oyekan |
| Born | 30 Oṣù Kẹfà 1911 (N.S.: 30 June 1911) Lagos, Southern Nigeria Protectorate |
| Died | 1 March 2003 (ọmọ ọdún 91) Lagos, Nigeria |
| Burial | Iga Idunganran |
| Religion | Christianity |
Adeyinka Oyekan II (tí a bí ní ọgbọ̀njọ́ oṣù kẹfà ọdún 1911 – tí o sì kú ní ọjọ kínní oṣù kẹta ọdún 2003) jẹ Oba ilu Eko lati ọdún 1965 sí ọdún 2003. Òun ní ọmọ ọmọ Ọba Oyekan I . [1]
Ìbẹ̀rẹ̀ Ìgbésí ayé ati ẹkọ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Baba Adeyinka jẹ olukọ Methodist, ọmọ ọba Kusanu Abiola Oyekan. [2] Adeyinka Oyekan lọ si ilé-ìwé gíga Methodist Boys' High School, Eko, ati King's College, Eko ṣáájú ki o to kọ ẹkọ ìmọ̀n ògùn ni Yaba College of Higher Education. Onìgbàgbọ́ olufokansin, ọmọ ijọsin Methodist Tinubu ní ati olùkọ ilé-ìwé ọjọ ìsinmi tẹlẹ. [2]
Iṣẹ-ṣiṣe
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Lẹ́yìn tí Adeyinka jáde ní ilé ẹ̀kọ́ gíga Yaba Higher College, wọ́n fún ní iṣẹ ní ilé ìwòsàn General, Eko ní ọdún 1933. [3]
Ni ọdún 1965, wọn fi Adeyinka jẹ Ọba, lẹyìn náà o di ọmọ ẹgbẹ ilè àwọn olóyè ni iwọ̀ Oorùn; eyi ṣẹlẹ lasiko wahala kan ni ẹkun ìwọ̀-oòrùn Nàìjíríà ti o fa ìsọnù ẹmi lọ. Ó jọba gẹ́gẹ́ bí Ọba Èkó láti ọdún 1965 títí di ọdún 2003. Adeyinka Oyekan jẹ́ ẹlẹ́sìn Krístì Ọba Èkó kejì, àkọ́kọ́ ni Ibikunle Akitoye . [2] A kà á sí ẹni pacifist ati oluṣe afárá nígbà ijọba rẹ. [4] Adeyinka Oyekan tun jẹ oniwosan oogun labẹ Igbimọ Methodist ni Amachara ati Umuahia ni Ipinlẹ Ìlà-orùn ààrin ti Nàìjíríà nigbana. Lakoko Ogun Agbaye II, o ṣiṣẹ bi Ọga Ọlọpa ni Ẹka Ambulance Kẹta 81st (WA). Lẹ́yìn iṣẹ́ ológun rẹ̀, wọ́n fún nise ni ilé iṣẹ́ ìlera ní ìpínlẹ̀ Èkó. [2]
Awọn iran
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ojúlówó ọmọ kàn ni ọmọkùnrin rẹ, Oba Mobandele Oyekan ti Ilado, ti apẹja orúkọ rẹ njẹ Onilado ti Ilado .
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Moshood Ademola Fayemiwo, PhD; Margie Neal-Fayemiwo, Ed.D (6 July 2017). ASIWAJU: The Biography of Bolanle Ahmed Adekunle Tinubu. Strategic Book Publishing & Rights Agency, 2017. pp. 288. ISBN 9781946539434.
- 1 2 3 4 Folami. A History of Lagos, Nigeria: The Shaping of an African City. Exposition Press, 1982. ISBN 9780682497725.
- ↑ Musliu Olaiya Anibaba (2003). A Lagosian of the 20th century: an autobiography. Tisons Limited. p. 102. ISBN 978-9-783-5571-16. https://books.google.com/books?id=Y9AuAQAAIAAJ&q=adeyinka+oyekan+colonial+Lagos.
- ↑ http://www.thisdayonline.com/archive/2003/03/09/20030309cov01.htmlTHISDAYonline Archived 2007-09-30 at the Wayback Machine.
Ita ìjápọ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- Adeyinka Oyekan's obituary
- Jeti irohin. Fọto ti Oyekan, 1971