African Food Network
Ìrísí
| Type | Àdáni |
|---|---|
| Founder(s) | Kevin Eze |
| Headquarters | Àbújá, Nàìjíríà |
| Industry | Oúnjẹ |
| Website | www.afrifoodnetwork.com |
African Food Network, tí a mọ̀ sí Afri Food Network, jẹ́ ojú òpó wẹ́ẹ́bù àti ilé-iṣẹ́ tí a ṣe fún oúnjẹ àti ìgbé-ayé ilẹ̀ Áfíríkà. Kevin Eze ni ó dá ojú òpó yìí sílẹ̀ ní oṣù January, ọdún 2017 ní Abuja, Nàìjíríà.
Ìtaǹ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]African Food Network bẹ̀rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ojúlé ayélujára kan pẹ̀lú ààtò oúnjẹ tí kò tó àádọ́ta ní ọún 2017 tí ó sì ti di ọ̀kan lára àwọn ìwé-àkọsílẹ̀ ààtò oúnjẹ Áfíríkà tó tóbi jùlọ lórí ayélujára pẹ̀lú ààtò oúnjẹ tó lé ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta tí ó ti ọwọ́ àwọn òǹkọ̀wé ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ wá.[1] A dá African Food Network sílẹ̀ láti tún àyípadà ṣe sí ojú tí wọ́n fi ń wo oúnjẹ Áfíríkà ní àgbáyé, àwọn Alásè àti àwọn Alásè oúnjẹ abínibí, èyí tí olùdásílẹ̀ sọ.[2]
Àwọn ayẹyẹ tí wọ́n ṣe
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]| Year | Title | City | Country | Ref |
|---|---|---|---|---|
| 2021 | Ayẹyẹ Oúnjẹ àti Mímu Áfíríkà | Abuja | Nigeria | [3] |
| 2022 | Ayẹyẹ Oúnjẹ àti Mímu Áfíríkà | Accra | Ghana | [4] |
| 2022 | Ayẹyẹ Oúnjẹ àti Mímu Áfíríkà | Abuja | Nigeria | [5] |
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Largest online African food recipe database unveiled". Guardian newspaper. Retrieved 23 December 2018.
- ↑ "African Food Network to grow African cuisines and chefs globally". Vanguard newspaper. Retrieved 26 November 2017.
- ↑ "Day African Food and Drink Festival thrilled food lovers in Abuja". Guardian Newspaper. Archived from the original on 7 October 2021. Retrieved 3 October 2021.
- ↑ "African Food Network announces Accra, Ghana as next destination for their festival". Guardian Newspaper. Retrieved 18 January 2022.
- ↑ "African Food Festival will be live in Accra, Ghana this year – Co-founder of African Food Network reveals". Vanguard Newspaper. Retrieved 15 January 2022.
