Jump to content

African Food Network

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
African Food Network
TypeÀdáni
Founder(s)Kevin Eze
HeadquartersÀbújá, Nàìjíríà
IndustryOúnjẹ
Websitewww.afrifoodnetwork.com

African Food Network, tí a mọ̀ sí Afri Food Network, jẹ́ ojú òpó wẹ́ẹ́bù àti ilé-iṣẹ́ tí a ṣe fún oúnjẹ àti ìgbé-ayé ilẹ̀ Áfíríkà. Kevin Eze ni ó dá ojú òpó yìí sílẹ̀ ní oṣù January, ọdún 2017 ní Abuja, Nàìjíríà.

African Food Network bẹ̀rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ojúlé ayélujára kan pẹ̀lú ààtò oúnjẹ tí kò tó àádọ́ta ní ọún 2017 tí ó sì ti di ọ̀kan lára àwọn ìwé-àkọsílẹ̀ ààtò oúnjẹ Áfíríkà tó tóbi jùlọ lórí ayélujára pẹ̀lú ààtò oúnjẹ tó lé ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta tí ó ti ọwọ́ àwọn òǹkọ̀wé ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ wá.[1] A dá African Food Network sílẹ̀ láti tún àyípadà ṣe sí ojú tí wọ́n fi ń wo oúnjẹ Áfíríkà ní àgbáyé, àwọn Alásè àti àwọn Alásè oúnjẹ abínibí, èyí tí olùdásílẹ̀ sọ.[2]

Àwọn ayẹyẹ tí wọ́n ṣe

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
YearTitleCityCountryRef
2021Ayẹyẹ Oúnjẹ àti Mímu ÁfíríkàAbujaNigeria[3]
2022Ayẹyẹ Oúnjẹ àti Mímu ÁfíríkàAccraGhana[4]
2022Ayẹyẹ Oúnjẹ àti Mímu ÁfíríkàAbujaNigeria[5]

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "Largest online African food recipe database unveiled". Guardian newspaper. Retrieved 23 December 2018.
  2. "African Food Network to grow African cuisines and chefs globally". Vanguard newspaper. Retrieved 26 November 2017.
  3. "Day African Food and Drink Festival thrilled food lovers in Abuja". Guardian Newspaper. Archived from the original on 7 October 2021. Retrieved 3 October 2021.
  4. "African Food Network announces Accra, Ghana as next destination for their festival". Guardian Newspaper. Retrieved 18 January 2022.
  5. "African Food Festival will be live in Accra, Ghana this year – Co-founder of African Food Network reveals". Vanguard Newspaper. Retrieved 15 January 2022.