Agẹmọ (Òrìsà )
| Agẹmọ | |
|---|---|
Messenger of the gods | |
| Member of Orisha | |
| Script error: The module returned a nil value. It is supposed to return an export table. | |
| Venerated in | Yoruba religion |
| Animals | Chameleon |
| Color | Color-changing |
| Region | Yorubaland |
| Ethnic group | Yoruba people |
Nínú ẹ̀sìn Yorùbá, Agẹmọ jẹ́ ògà ọmọ ogun tí ń ṣe ìránṣẹ́ ọlọ́run Ọlọ́run, olórí àwọn òrìṣà ilẹ̀ Yorùbá (tí a mọ̀ sí Orishas ). Agẹmọ N'ma ń gbe awọn ìfiránṣé láàrin àwọn òrìṣà . [1]
Àwọn ìtàn ayé àtijọ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Nínú ìtàn kan, Agẹmọ bá ògá rẹ, Ọlọ́run borí ninu idije pelu Olokun, orisha Odò. Ọlókun ni ọgbọ́n pípa asọ láró àti wíwun Asọ, èyí ló jẹ́ kí ó rò pe òun ga ju gbọgbọ Òrìsà tó kù, pẹ̀lú Ọlọ́run. Ó pe Ọlọ́run níjà sí ìdíje asọ̀ ṣíṣẹ láti mọ ẹni tí ó ga jùlọ ní tòótọ́. Ọlọ́run sọ fún Agẹmọ pé kí ó sọ fún Ọlókun kó fi aṣọ rè tó dára jù han, bo ba wu lórí oun, yoo gbà láti díje naa. Agẹmọ, tí ó jẹ́ Ògà, ní ànfàní lati ṣe àpẹrẹ gbọgbọ aṣọ tí Olokun ṣe. Olókun rò pé bí òjíṣẹ́ Ọlọ́run bá lè tètè tún iṣẹ́ òun ṣe, òun kì yóò bá Ọlọ́run fúnra rẹ̀ dọ́gba, ó sì jẹ́wọ́ ìjákulẹ̀. [1] [2] [3]
Ìjọsìn
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Agẹmọ je òrìṣà pàtàkì àwọn ará Ìjẹ̀bú . Ẹgbé Agẹmọ tan ní pàtàkì nípasẹ̀ iyipada ti awọn obinrin tiwọn ó rí ọmọ bi, òpòlọpò nínú wọn lọ sí ọdọ òrìṣà láti wá ìwòsàn sí àìlómọ wọn sàn. Nígbà tí wọn bímọ, wọ́n jọ̀wọ́ ara wọn àti àwọn ọmọ wọn fún ìjọsìn Agẹmọ. [4] [5]
Láyé àtijọ́, ènìyàn ni wọn máa fi ń rúbọ fún Agemọ́, wọ́n sì máa ń jẹ́ kí ẹni tí wọ́n fi rúbọ yìí jẹrà nínú ojúbọ. Nígbà Tó yá, ìyípadà wáyé, tí ó ṣe okùnfà bí wọ́n ṣe ń fi màálù rúbọ ní ọdún kan, ènìyàn rúbọ ní ọdún tó tẹ́lẹ̀. Ọdún tí wọ́n bá fi ènìyàn rúbọ ni wón ń pè ní Akọ Ọdún, odun ti wọn bá fi màálù rúbọ ni wọ́n ń pè ní Abọ Ọdún. Nígbà tí ifi ènìyàn rúbọ paré, Akọ Ọdún di ọdún tí a ń fi Akọ màlúù rúbọ, Abọ Ọdún si di ọdún tí a nfi abọ màlúù rúbọ. Dípò tí ìrúbọ ènìyàn tí wá jeki ènìyàn na jẹrà, ìrúbọ tí màálù je eyi ti awon ènìyàn a jẹ ẹran màálù na[6]
Ayẹyẹ Agemọ jẹ ajọdun iboju ti aṣa ti aṣa ni ọpọlọpọ awọn ilé Yorùbá ṣugbọn o gbajúmò púpò láàrin awọn ènìyàn Ìjẹ̀bú nipinlẹ Ogun . Ayẹyẹ àti awọn àṣà ìrúbọ ti o tẹle ni a ṣe lati bu ọlá fun Agẹmọ, tí wọ́n gbàgbọ́ pé ó jẹ́ olú dáàbò fún àwọn ọmọdé ati ẹnití ó ṣe ààbò ọjọ́ iwájú àwọn ènìyàn Ìjẹ̀bú nípasẹ̀ ìbùkún rẹ̀ . [7]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- 1 2 Lynch, Patricia (May 1, 2010). African Mythology A to Z. Chelsea House Publications. ISBN 978-1604134155. https://books.google.com/books?id=ISBN1604134151.
- ↑ Abarry, Abu (1996). African Intellectual Heritage: A Book of Sources. Temple University Press. ISBN 1566394031. https://books.google.com/books?id=AxXE65flKPwC.
- ↑ Duane, O.B. (2001). African Myths and Legends. Brockhampton Press. ISBN 1860193676. https://books.google.com/books?id=qH5QCt0R5CgC.
- ↑ Ojo, Olatunji (2009). "'Heepa' (Hail) Òrìşà: The Òrìsà Factor in the Birth of Yoruba Identity". Journal of Religion in Africa 39 (1): 30–59. doi:10.1163/157006609X408211. ISSN 0022-4200. JSTOR 20696795. https://www.jstor.org/stable/20696795.
- ↑ Ojo, Olatunji (2008). "Beyond Diversity: Women, Scarification, and Yoruba Identity". History in Africa 35: 347–374. doi:10.1353/hia.0.0015. ISSN 0361-5413. JSTOR 25483727. https://www.jstor.org/stable/25483727.
- ↑ Awolalu, J. Omosade (1973). "Yoruba Sacrificial Practice". Journal of Religion in Africa 5 (2): 81–93. doi:10.2307/1594756. ISSN 0022-4200. JSTOR 1594756. https://www.jstor.org/stable/1594756.
- ↑ "How Agemo festival put Ijebuland on hold for seven days - Vanguard News" (in en-US). Vanguard News. 2017-07-14. https://www.vanguardngr.com/2017/07/agemo-festival-put-ijebuland-hold-seven-days/.