Aissa Koli
| Aissa Koli | |
|---|---|
Magira of the Kanem–Bornu Empire | |
| Reign | 16th century (7–8 years) c. 1563–1570[lower-alpha 1] |
| Predecessor | Abdullah IV Dunamami |
| Successor | Idris IV Alooma |
| Dynasty | Sayfawa dynasty |
| Father | Unclear; Muhammad VI Aminami, Ali II Zainami, or Dunama VI Muhammad |
Aissa Koli tabi Aisa Kili (Āʾisha Kili [1] ), tí a máa ń pè ní Aisa Kili Ngirmaramma nígbà míì, [2] [3] [lower-alpha 2] jẹ́ Ọba Kanem–Bornu ní àárín ọ̀rúndún kẹrìndínlógún sí ìparí, ó jọba ní nǹkan bí ọdún 1563 sí 1570. [lower-alpha 3] Wọ́n má ń pè ní magira tí ó tún túmọ̀ si" ìyá ayaba ", Aissa jẹ́ ọ̀kan lára àwọn àṣàyàn obìnrin díẹ̀ tí ó ṣàkóso ìjọba náà, tí ó tún jẹ́ ọ̀kan ṣoṣo tí a mọ̀ tí ó jẹ́ Ọba pẹ̀lú Agbára rẹ̀ . [3] [lower-alpha 4] Nínú àwọn ìtàn afenuso ninu àṣà ile Bornuan, Aissa sì jẹ́ ẹni iyì botilejepe àìfohùnṣọ̀kan wà nínú kúlẹ̀kúlẹ̀ Ìsèjoba rẹ̀.
Ìgbésí ayé
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Àwọn àìfohùnṣọ̀kan wa nínú orisun ìbátan ìdílé Aissa àti àwọn kúlẹ̀kúlẹ̀ Ìsèjoba rẹ̀. Nínú àwọn àṣà orin àtọwọ́dọ́wọ́ ní Bornu wọn sì mọn bù orí yín fún Aissa[7] ṣùgbọ́n nínú àwọn ìwé òpìtàn Arab, wọn sábà fi ọ̀rọ̀ ìtàn rẹ̀ sínú ìwé ìtàn [2] [7] Èyí je lára àwọn ọ̀rọ̀ kan tí wọ́n sábà máa ń sọ nípa bí àwọn onkotan ṣe mọn yọ kúrò tàbí kí wọ́n mo bù iyì tó bó se yẹ fún awon obabìnrin tó bá jé alágbára. [2] [7]
Wọ́n sọ pé Aissa ló gba ipò lẹ́yìn Mai Abdullah IV Dunamami nígbà tí kò sì ọmọ kùnrin tí yíò jogún ìté rẹ. Ìbátan rẹ sì ìran tí ón jọba ní àkókò Sayfawa yàtò síra won látàrí orísun tí ò yàtò sì arawon.
Nínú àwọn ìwé ìtàn àti ìtúpalẹ̀ àwọn ìwé ìtàn Bornuan tí wọ́n ṣe ní àwọn nkan bí ọ̀rúndún ọdún sẹ́yìn, ó tọ́kasí pé bí kò bá jẹ ọmọ Muhammad Aminami Palmer, 1936) yio je ọmọbìnrin Dunama VI Muhammad Urvoy, 1941). Ìwé ìtàn mìíràn so pé ní ọmọbìnrin Mai Ali II Zainami ni yo je tàbí kí ó jẹ́ Ẹ̀gbọ́nbinrin Adelé Mai Idris IV Alooma. Nínú ìtàn, Aissa ni ìtàn fi idi rẹ múlè pé ó ṣe ijoba títí di ìgbà tí Idris fi dàgbà to ṣe ijoba, lẹ́yìn na ni ó kúrò ní orí ipò fún. Aissa sì tẹ̀síwájú gẹgẹbi olùdánòràn pàtàkì sí Idris leyin igba ti o fi ipò òye òun kalẹ̀ fun Idris tí wọ́n sì mọ bù ìyìn fún gẹgẹbi ẹni tí ó kó Idris ni òṣèlú.
Nínú ìtàn kan tí ó fi Aissa hàn gẹ́gẹ́ bí ọmọbìnrin Ali Kejì, Dunama Kẹfà (ẹni tí ó gba ipò Ali) pa gbogbo àwọn ọmọ Ali, àyàfi Idris tí ó dà sí ti ìyá rẹ, Amsa sì rán lọ sí Bilala ni ìkòkò. Nígbà tí Abdullahi IV ẹni to je Aremo fún Dunama, ní àkókò tí Aissa gùn orí ipò ọba, kò mọn pé Idris sì wá láyé. Abala ìtàn mi tún sọ pé, Aissa ni ìya Ali bóyá látàrí orúkọ oyè Magira tí ó túmọ̀ sí Iya Ọba. Eleyi jẹ ìró nítorí pé nínú àwọn ìtàn mìíràn tí ó fi di múlè, pé Amsa ni orúkọ ìyá Idris. Ní ọdún 1966, Ronald Cohen so pé oṣese kojepe ìlò Magira gẹ́gẹ́bi orúkọ lè túmò sí wípé Aissa je okan lara awon ìyàwó Ali II ti kí sì ṣe pé ó jẹ́ ìyá Idris lèyí tí yíò fi idi rẹ múlè wípé kò ní ìbátan pelu awon Ọba yòókù.
Àwọn Àkíyèsí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid
<ref>tag; no text was provided for refs named "AissaReign". - ↑ Richmond Palmer translated Kili Ngirmaramma in 1912 as "lady of the great white horse".[4]
- ↑ Specific regnal years of rulers of the Kanem–Bornu Empire are calculated by backdating from known events using their regnal lengths and vary between sources. Palmer (1936) assigned Aissa eight regnal years and dated her reign to 1562/1563–1570. Urvoy (1941) assigned her seven regnal years and dated her reign to 1573–1580.[5] She is sometimes omitted entirely from lists[5] or designated as a co-ruler of Idris IV Alooma.[6] Later authors have generally followed Palmer's dates, placing her reign in c. 1563–1570,[3][7] but alternate dates also continue to be used, such as 1497–1504.[8] Some authors assign Aissa a longer reign, such as 1570–1580[9] or even 1560–1610,[10] on an unclear basis.
- ↑ The earlier 11th-century ruler Hu has been suggested to have been a woman though this is unproven.[11] In the 12th century, Fasama also wielded considerable power as regent but she formally ruled on behalf of her young son Biri I Uthman.[12]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ è l Bosworth, Clifford Edmund (2012). The New Islamic Dynasties: A Chronological and Genealogical Manual. Edinburgh University Press. pp. 126–127. ISBN 978-0-7486-2137-8. https://books.google.com/books?id=maQxEAAAQBAJ.
- 1 2 3 Lipschutz, Mark R. (1986). Dictionary of African Historical Biography. University of California Press. pp. 11. ISBN 978-0-520-06611-3. https://www.google.com/books/edition/Dictionary_of_African_Historical_Biograp/QYoPkk04Yp4C. Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid
<ref>tag; name ":2" defined multiple times with different content. - 1 2 3 Sheldon, Kathleen (2016). Historical Dictionary of Women in Sub-Saharan Africa. Rowman & Littlefield. pp. 26, 168. ISBN 978-1-4422-6293-5. https://books.google.com/books?id=HwqQCwAAQBAJ&pg=PA168.
- ↑ Palmer, H. R. (1912). "The Bornu Girgam". Journal of the Royal African Society 12 (45): 78–79. ISSN 0368-4016. https://www.jstor.org/stable/716085.
- 1 2 Cohen, Ronald (1966). "The Bornu King Lists". Boston University Papers on Africa: Volume II: African History. Boston University Press. pp. 55, 59, 82–83. https://archive.org/details/bostonuniversity02bost.
- ↑ Bosworth, Clifford Edmund (2012). The New Islamic Dynasties: A Chronological and Genealogical Manual. Edinburgh University Press. pp. 126–127. ISBN 0-7486-2137-7. https://www.google.com/books/edition/New_Islamic_Dynasties/maQxEAAAQBAJ.
- 1 2 3 4 Coquery-vidrovitch, Catherine (2018). "Queen Mothers and Female Regents" (in en). African Women: A Modern History. Routledge. ISBN 978-0-429-98212-5. https://www.google.com/books/edition/African_Women/72dNDwAAQBAJ.
- ↑ Greenspan, Karen (1994) (in en). The Timetables of Women's History: A Chronology of the Most Important People and Events in Women's History. Simon & Schuster. pp. 135. ISBN 978-0-671-67150-1. https://www.google.com/books/edition/The_Timetables_of_Women_s_History/OjQpAAAAYAAJ.
- ↑ Stewart, John (2024) (in en). African States and Rulers (3 ed.). McFarland. p. 36. ISBN 978-1-4766-1707-7. https://books.google.com/books?id=GZMuEQAAQBAJ&pg=PA36.
- ↑ Falola, Toyin; Amponsah, Nana Akua (2012) (in en). Women's Roles in Sub-Saharan Africa. ABC-CLIO. pp. xii. ISBN 978-0-313-38545-2. https://www.google.com/books/edition/Women_s_Roles_in_Sub_Saharan_Africa/Uk_EEAAAQBAJ.
- ↑ Koslow, Philip (1995). Kanem-Borno: 1,000 Years of Splendor. Chelsea House Publishers. pp. 19–20. ISBN 0-7910-3129-2.
- ↑ Barth, Heinrich (1857) (in en). Travels and Discoveries in North and Central Africa: Being a Journal of an Expedition Undertaken under the Auspices of H.B.M.'s Government, in the Years 1849–1855. Longmans. pp. 635. https://www.google.com/books/edition/Travels_and_Discoveries_in_North_and_Cen/la_zIUj0oiwC.