Jump to content

Akinpelu Johnson

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Babatunde Colenso Akinpelu Johnson [1] (wọ́n bí i ní ọdún 1965)[2] jẹ́ Bísọ́ọ̀bù ìjọ Ángílíkáàní (Anglican bishop) ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà:[3] Ó di Bísọ́ọ̀bù ìjọ Ángílíkáànì tí ìlú Èkó èyí tí ó wà ní Lagos Mainland láti ọdún 2016.[4]

Alàgbà Johnson kẹ́kọ̀ọ́ jáde ní Immanuel College of Theology, Ibadan, King's College London àti University of Kent. Wọ́n yàn án ní ọdún 1990, ó sì ṣiṣẹ́ dipò mún ní All Saint's, Yaba, lẹ́yìn èyí ni ó di Vicar ti St. John, Aroloya. Ó di Archdeacon ti agbègbè Apapa lẹ́yìn náà ni ó di Provost ti ìjọ náà.[5]

  1. "Latest On Rt. Rev. Akinpelu Johnson". The Guardian Nigeria News. Retrieved 2020-12-08.
  2. "Johnson, Anglican Bishop Lagos Mainland Diocese @ 55: Sustaining the family legacy [[:Àdàkọ:Pipe]] Church Times Nigeria - News, features and more". churchtimesnigeria.net. 16 May 2020. Retrieved 2020-12-08. URL–wikilink conflict (help)
  3. Anglican Communion Office. "Position - Nigeria - Lagos Mainland". anglicancommunion.org. Retrieved 2020-12-08.
  4. "2017 Bishop's Charge | Egba Anglican Diocese". egbadiocese.org. Archived from the original on 2021-08-28. Retrieved 2021-03-09.
  5. "Akinpelu Johnson:The fifth bishop from Nigeria's 'Levitical Dynasty - Vanguard News". vanguardngr.com. 16 July 2016. Retrieved 2020-12-08.

Àdàkọ:Subject bar

Àdàkọ:Provinces (with dioceses) in the Church of Nigeria


Àdàkọ:Nigeria-Anglican-bishop-stub