Akinpelu Oludele Adesola
Ìrísí
Akinpelu Oludele Adesola | |
|---|---|
| Fáìlì:Akinpelu Oludele Adesola.png | |
| 5th Vice chancellor of the University of Lagos | |
| In office 1981–1988 | |
| Asíwájú | Babatunde Kwaku Adadevoh |
| Arọ́pò | Nurudeen Oladapo Alao |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | 6 November 1927 |
| Aláìsí | 29 May 2010 (ọmọ ọdún 82) |
| Ẹgbẹ́ olóṣèlú | Non-Partisan |
Akinpelu Oludele Adesola (tí a bí ní ọjọ́ kẹfà oṣù kọkànlá ọdún 1927 – ọjọ kọkàndinlọ́gbọ̀n oṣù kàrún ọdún 2010) jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n nínú iṣẹ́ abẹ ni Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà, alabojuto ètò ẹkọ ati igbakeji alakoso ti Fasiti ìlú Eko . [1] [2]
Bàba rẹ ni Olóyè Bámgbóṣé Fasina Adesola MBE ( Bariyun tí ìlú Ìṣagá àti Bajito tí ìlú Ibara ni Ìpínlẹ̀ Abẹ́òkúta). Ó dára pọ̀ mọ́ ilé ìwé Saint Jude ni Èbúté Mẹ́ta ni ìlú Èkó níọdún 1935, tí ó fi taratara síse gẹ́gẹ́ bí akọrin ni Sunday School. Ìdílé Adesola jẹ́ ìdílé onígbàgbọ́ Kírísítì,wọn sì nífẹ̀ẹ́ sì àwọn orin ìgbàgbó, idilẹ́ náà sì kún fún àwọn olólùfẹ́ orin Kírìsítì, tí wọ́n sì gbádùn awon orin bẹ́ẹ̀, wọn nífẹ̀ẹ́ láti má fi ṣe ìdárayá àti pé wọ́n á máa kọ àwọn orin to jẹ́ mo orin ẹ̀sìn. [3]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Wo tun
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- Babatunde Kwaku Adadevoh
- Akojọ ti awọn igbakeji Chancellor ni Nigeria
- University of Lagos