Jump to content

Akinpelu Oludele Adesola

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Akinpelu Oludele Adesola
Fáìlì:Akinpelu Oludele Adesola.png
5th Vice chancellor of the University of Lagos
In office
1981–1988
AsíwájúBabatunde Kwaku Adadevoh
Arọ́pòNurudeen Oladapo Alao
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí6 November 1927
Aláìsí29 May 2010(2010-05-29) (ọmọ ọdún 82)
Ẹgbẹ́ olóṣèlúNon-Partisan

Akinpelu Oludele Adesola (tí a bí ní ọjọ́ kẹfà oṣù kọkànlá ọdún 1927 – ọjọ kọkàndinlọ́gbọ̀n oṣù kàrún ọdún 2010) jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n nínú iṣẹ́ abẹ ni Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà, alabojuto ètò ẹkọ ati igbakeji alakoso ti Fasiti ìlú Eko . [1] [2]

Bàba rẹ ni Olóyè Bámgbóṣé Fasina  Adesola  MBE ( Bariyun tí ìlú Ìṣagá àti Bajito tí ìlú Ibara ni Ìpínlẹ̀ Abẹ́òkúta). Ó dára pọ̀ mọ́ ilé ìwé Saint Jude ni Èbúté Mẹ́ta ni ìlú Èkó níọdún 1935, tí ó fi taratara síse gẹ́gẹ́ bí  akọrin ni Sunday School. Ìdílé Adesola jẹ́ ìdílé onígbàgbọ́ Kírísítì,wọn sì nífẹ̀ẹ́ sì àwọn orin ìgbàgbó, idilẹ́ náà sì kún fún àwọn olólùfẹ́ orin Kírìsítì, tí wọ́n sì gbádùn awon orin bẹ́ẹ̀, wọn nífẹ̀ẹ́ láti má fi ṣe ìdárayá àti pé wọ́n á máa kọ àwọn orin to jẹ́ mo orin ẹ̀sìn. [3]