Jump to content

Aliyu Sabi Abdullahi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Aliyu Sabi Abdullahi

Minister of State for Agriculture and Food Security
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
21 August 2023
ÀàrẹBola Tinubu
AlákósoAbubakar Kyari
AsíwájúMustapha Baba Shehuri
Senator for Niger North
In office
9 June 2015  11 June 2023
AsíwájúIbrahim Musa
Arọ́pòAbubakar Sani Bello
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí10 Oṣù Kínní 1967 (1967-01-10) (ọmọ ọdún 59)
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressives Congress
Occupation
  • Politician
  • veterinary surgeon

Aliyu Sabi Abdullahi CON (abi ní ọjọ́ kẹwàá Oṣù Kíní ọdún 1967) jẹ́ oníṣègùn oníṣẹ́abẹ fún ọ̀sìn ẹranko àti minisita kejì fún iṣẹ́ ọ̀gbìn àti ààbò oúnjẹ lọ́wọ́lọ́wọ́ nì orílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Ó ti ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà tí ó ṣojú Agbègbè apá Àríwá ti ìpínlẹ̀ Niger láti ọdún 2015 si 2023, [1] ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà kẹjọ àti ìkẹsàn-án.[2][3][4] Ó jẹ́ igbákejì alága tó ǹ rísí ìhùwàsí àwọn aṣòfin ti ilé ìgbìmọ̀ àgbà kẹsàn-án. [5][6]

Iṣẹ́ olóṣèlú

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Abdullahi kópa gẹ́gẹ́ bí olùdíje nínú ìdìbò tí ó wáyé ní ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ́n oṣù kẹta ọdún fún ipò láti lọ ṣojú ẹkùn àríwá Niger ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà tí a sì kéde rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó borí.

Níbi ìdìbò tí ó wáyé ní oṣù kejì ọdún 2019, a dìbò yàn án ní ẹlẹ́ẹ̀kejì láti lọ ṣojú ẹkùn ìdìbò rẹ̀ èyí tíì ṣe Àríwá ìpínlẹ̀ náìjà tó sì borì pẹ̀lú ìbò tò jẹ́ 161,420, tí ẹni tí ó tẹ̀lée tì orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Hon. Muhammad Sani Duba láti inú ẹgbẹ́ òṣèlú ti People's Democratic Democratic (PDP) ní ìbò 77,109.

Àwọn Àmì Ẹ̀yẹ

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní oṣù kẹwàá ọdun 2022, wọ́n fún un ní àmì-ẹ̀yẹ ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bíi Olùdarí ti Orílẹ̀-èdè Niger (CON) láti ọwọ́ olórí orílẹ̀ èdè ọ̀gágun Muhammadu Buhari. [7]