Jump to content

Amelia Okoli

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Amelia Okoli
Òrọ̀ ẹni
Ọjọ́ìbí14 May 1941
Ọjọ́aláìsí1 November 2017(2017-11-01) (ọmọ ọdún 76)
America

Amelia Okoli Okpalaoka tí wọ́n bí ní ọjọ́ kẹrìnlá oṣù Karùn-ún ọdún 1941, tí ó sì kú ní ọjọ́ kíní oṣù kọkànlá ọdún 2017, jẹ́ eléré ìdárayá àti eléré orí pápá láti Nàìjíríà. Ó ṣe amọ̀ja nínú ìṣẹ̀lẹ̀ fífò gíga ní gbogbo ìgbà iṣẹ́ rẹ̀.

Okoli ṣe aṣojú Nàìjíríà ní Èré Olimpiiki Àgbáyé ọdún 1964. Ní ọdún 1965, ní Èré Gbogbo Áfíríkà ní Ìwọ̀-Òòrùn Áfíríkà, ó gba àmì ẹ̀yẹ goolu fún orílẹ̀-èdè abinibi rẹ̀.

Ní ọdún 1958, Okoli tún kópa nínú Èré Ìjọba Gẹ̀ẹ́sì àti Ìdíje Ìṣeré Gíga Àgbáyé, níbi tí ó ṣe ipò kẹ̀wá.