Ango Abdullahi
| Ango Abdullahi | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | 13 December 1938 Old Giwa Village, Kaduna |
| Ọmọ orílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Iléẹ̀kọ́ gíga | University of Ibadan, Ahmadu Bello University |
| Olólùfẹ́ | Senator Aisha Alhassan |
| Àwọn ọmọ | Ango Sadiq Abdullahi |
| Awards | Commander of the Order of the Niger (CON), Magajin Rafin Zazzau |
Ango Abdullahi je ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà omowe àti olóṣèlú. O jẹ Igbákejì giwaYunifásítì ti Ahmadu Bello nígbà kàn ri àti pè o ti jẹ aṣoju ẹkun ìdìbò Iwọ-oorun Zaria tẹlẹ ni ìpínlè Kaduna. [1] [2]
Ìgbésí àyè ara ẹni
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ango Abdullahi je Mùsùlùmí o si je bàbá Ango Sadiq Abdullahi ọmọ ile aṣojú sọ fín ni orílè-èdè Nàìjíríà.[2] wọn bi ni ọjọ 13 Oṣu kejìlá ọdun 1938 ni abúlé Giwa atijọ. O se ìgbéyàwó pẹlu Olóògbé Senator Aisha Jummai Alhassan, ti a tun mọ si Màmá Taraba.
Eto ẹ̀kọ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]O bẹrẹ ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ ni ilé ìwé Kali ni ọdun 1944 kí ó tó kọjá sì ilé-ìwé Giwa ni ọdun kàn náà. O lọ si ile-ẹkọ gírámà Barewa láàrin ọdun 1953 sì ọdun 1958, ó kàwé gboyè ni Yunifásítì ìlú Ibadan àti Yunifásítì Ahmadu Bello ni ìlú Zaria kí ó tó di adarí àgbá ni ilẹ̀ ẹ̀kọ́ gíga Ahmadu Bello ni ìlú Zaria.[3]
Àwọn àmì ẹyẹ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]O gbà àmín ẹyẹ ni ọdun 2007 gẹgẹbi Alákóso Niger, CON láti ọwọ ìjọba àpapò orílẹ̀èdè Nàìjíríà, o sì tún jé òye Magajin Rafin Zazzau (Alábòójútó ti omi ati awọn ohùn elo ti ọ̀gbìn) nipasẹ ilu abínibí bí rẹ ìlú Zaria Emirate ni ọdun kanna. [4] [1]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- 1 2 https://www.vanguardngr.com/2023/01/vanguard-award-ango-abdullahi-accomplished-academic-elder-statesman/amp/
- 1 2 "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2024-12-13. Retrieved 2024-12-29.
- ↑ https://blerf.org/index.php/biography/abdullahi-prof-ango/
- ↑ https://www.vanguardngr.com/2023/01/vanguard-award-ango-abdullahi-accomplished-academic-elder-statesman/amp/