Jump to content

Ango Abdullahi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Ango Abdullahi
Ọjọ́ìbí13 December 1938
Old Giwa Village, Kaduna
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigerian
Iléẹ̀kọ́ gígaUniversity of Ibadan, Ahmadu Bello University
Olólùfẹ́Senator Aisha Alhassan
Àwọn ọmọAngo Sadiq Abdullahi
AwardsCommander of the Order of the Niger (CON), Magajin Rafin Zazzau

Ango Abdullahi je ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà omowe àti olóṣèlú. O jẹ Igbákejì giwaYunifásítì ti Ahmadu Bello nígbà kàn ri àti pè o ti jẹ aṣoju ẹkun ìdìbò Iwọ-oorun Zaria tẹlẹ ni ìpínlè Kaduna. [1] [2]

Ìgbésí àyè ara ẹni

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ango Abdullahi je Mùsùlùmí o si je bàbá Ango Sadiq Abdullahi ọmọ ile aṣojú sọ fín ni orílè-èdè Nàìjíríà.[2] wọn bi ni ọjọ 13 Oṣu kejìlá ọdun 1938 ni abúlé Giwa atijọ. O se ìgbéyàwó pẹlu Olóògbé Senator Aisha Jummai Alhassan, ti a tun mọ si Màmá Taraba.

O bẹrẹ ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ ni ilé ìwé Kali ni ọdun 1944 kí ó tó kọjá sì ilé-ìwé Giwa ni ọdun kàn náà. O lọ si ile-ẹkọ gírámà Barewa láàrin ọdun 1953 sì ọdun 1958, ó kàwé gboyè ni Yunifásítì ìlú Ibadan àti Yunifásítì Ahmadu Bello ni ìlú Zaria kí ó tó di adarí àgbá ni ilẹ̀ ẹ̀kọ́ gíga Ahmadu Bello ni ìlú Zaria.[3]

Àwọn àmì ẹyẹ

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

O gbà àmín ẹyẹ ni ọdun 2007 gẹgẹbi Alákóso Niger, CON láti ọwọ ìjọba àpapò orílẹ̀èdè Nàìjíríà, o sì tún jé òye Magajin Rafin Zazzau (Alábòójútó ti omi ati awọn ohùn elo ti ọ̀gbìn) nipasẹ ilu abínibí bí rẹ ìlú Zaria Emirate ni ọdun kanna. [4] [1]