Ayélóyún
Qamardeen Odunlami | |
|---|---|
| Orúkọ àbísọ | Qamardeen Yusuf Odunlami |
| Ọjọ́ìbí | 27 Oṣù Kẹjọ 1973 Lagos state, Nigeria |
| Ìbẹ̀rẹ̀ | Ilorin, Kwara state |
| Irú orin | |
| Occupation(s) |
|
| Years active | 1992–present |
Qamardeen Yusuf Odunlami ( tí a bí ní ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n oṣù kẹjọ ọdún 1973) [1] tí gbogbo ènìyàn mọn sí orúkọ orí ìtàgé rẹ̀ tín ṣe Ayéloyun, ẹni tí a mọ̀ sí olórin àti olùṣeorin ẹ̀sìn Islam ní Nàìjíríà. Ó gbé àwo orin àkọ́kọ́ rẹ̀ jáde Taqwallah ní ọdún 1994, àwo orin rẹ̀ Igbeyawo sì jáde ní ọdún 2003, èyí tí ó jẹ́ àwo orin kẹsàn-án rẹ̀, ó sì mú kí ó gbajúmọ̀, kí o sì lókìkí.
Ìbẹ̀rẹ̀ Ìgbésí ayé àti ẹ̀kọ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]A bí Ayeloyun ní Agege, Èkó, Nàìjíríà sì ìdílé ọlọ́mọ méje. Ní ọdún 2006, wọn gbàá wọlé sí Yunifásítì Ilorin, Ìpínlẹ̀ Kwara láti kẹ́kọ̀ọ́ nípa Sharia àti Òfin Àpapọ̀ ṣùgbọ́n ó fi ilé ìwé náà sílẹ̀ láti gbájú mọ́ iṣẹ́ orin. [2] [3]
Iṣẹ́ orin
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Nígbà tí Ayeloyun wà ní kékeré, ó bẹ̀rẹ̀ sí í ṣe àwárí ìfẹ́ rẹ̀ sí orin nígbà tí ó wà ní kíláàsì èdè Lárúbáwá ní Marcaz, Agege, níbi tí ó ti kọrin nígbà Laylat al-Qadr àwẹ̀ Ramadan nítorí pé àwọn asíwájú rẹ̀ kò sí níbẹ̀ nígbà náà[4]. Ó bẹ̀rẹ̀ orin gẹ́gẹ́bí iṣẹ́ ní ọdún 1992 láti kojú ìbàjẹ́ ẹ̀sìn nínú Islam, ó sì gbé àwo orin àkọ́kọ́ rẹ̀ jáde ní ọdún 1994, ó sì ti gbé àwo orin mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n jáde tí ó sì gba ìyìn rẹ̀. [5]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ https://www.vanguardngr.com/2011/06/i-spent-18-months-in-my-mother%E2%80%99s-womb-aiyeloyun-2/
- ↑ https://thenationonlineng.net/day-a-fan-kissed-me-in-the-public-aiyeloyun/
- ↑ https://ayeloyungloballink.wordpress.com/2016/05/26/first-blog-post/
- ↑ https://www.nigeriafilms.com/celebrity-gossips/80-interviews/14740-i-still-want-to-be-a-lawyer-islamic-singer-ayeloyun[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
- ↑ https://thenationonlineng.net/day-a-fan-kissed-me-in-the-public-aiyeloyun/