Ayandotun Emmanuel
Ìrísí
Ayandotun Emmanuel tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ayọ̀ká Ológèdè jẹ́ òṣèré sinimá àgbéléwò ọmọ Ìwéréelé ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ , lápá ìwọ̀n oòrùn lórílẹ̀-èdè Nigeria[1]
Ìgbà èwe
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ó bẹ̀rẹ̀ ẹ̀kọ́ àkọ́bẹ̀rẹ̀ ní First Baptist Primary School, Ìwéréelé ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́. Ó kàwé gíga gírámà ní Oke Igano Model School, ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ kí ó tó dárí sí ìlú Èkó ní ti ó ti kàwé gíga si ní Aunty Ayo Comprehensive in Keffi[2]
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Iduh, Princess (2025-10-27). "How I transitioned from being househelp to acting – Ayandotun Emmanuel". The Nation Newspaper. Retrieved 2025-10-28.
- ↑ Nation, The (2018-11-02). "I WAS PAID N300 FOR MY FIRST MOVIE –VETERAN ACTRESS AYOKA". The Nation Newspaper. Retrieved 2025-10-28.