Jump to content

Ayobami Adebayo

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Ayobami Adebayo
Portrait of Adebayo
Ọjọ́ìbí29 Oṣù Kínní 1988 (1988-01-29) (ọmọ ọdún 38)
Lagos, Nigeria
Ẹ̀kọ́Obafemi Awolowo University
University of East Anglia
Notable workStay With Me (2017), A Spell of Good Things (2023)
Olólùfẹ́
Emmanuel Iduma (m. 2020)
Awards
Websiteayobamiadebayo.com

Ayobami Adebayo (a bí i ní ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n oṣù kìíní ọdún 1988) jẹ́ òǹkọ̀wé ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ẹni tí ìwé àròsọ rẹ̀ àkọ́kọ́, Stay With Me, gba ẹ̀bùn ilé-iṣẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ 9mobile fún ìwé ní ọdún 2017.[1] Wọ́n fún un ní ẹ̀bùn The Future Awards Africa Prizes fún Arts and Culture ní ọdún kan náà.[2][3]

Ìgbésí ayé ìbéèrè

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bí Adebayo ní ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n oṣù kìíní ọdún 1988 ní Èkó, orílè-èdè Nàìjíríà.[4] Ìdílé rẹ̀ kó lọ sí Ilésà lẹ́yìn náà sí Ilé-Ife, níbi tí ó ti lo ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà èwe rẹ̀ nínú ọgbà Yunifásítì ti Obafemi Awolowo University.[5]

Adebayo kẹ́ẹ̀kọ́ ní Yunifásítì Obafemi Awolowo, níbi tí ó ti gba oyè BA àti MA nínú Lítíréṣọ̀ ní èdè Gẹ̀ẹ́sì.[6] Ó tẹ̀síwájú láti kẹ́ẹ̀kọ́ Creative Writing ní Yunifásítì East Anglia, níbi tí wọ́n ti fún un ní ẹ̀bùn International Bursary.[7] Ó kẹ́ẹ̀kọ́ ìkọ̀wé pẹ̀lú Chimamanda Ngozi Adichie àti Margaret Atwood.[8]

Ní ọdún 2015, Financial Times kọ orúkọ Adebayo sí ọ̀kan lára àwọn òṣèré tíó jẹ́ gbajúmò nínú òǹkọ̀wé ní orílè-èdè Nàìjíríà.[9] Ó kọ ìwé ìtàn àkọ́kọ́ rẹ̀ tó ní àkọlé rẹ̀, Stay With Me, ní ọdún 2017 láti ọwọ́ Canongate Books.[10] Michiko Kakutani pè é ní “onítàn ìtàn tó tayọ” nínú àtúnyẹ̀wò fún The New York Times.[11] Ní ọdún 2019, Josette Chicheportiche túmọ̀ ìwé ìtàn náà sí èdè Faransé gẹ́gẹ́ bí Reste avec moi, Charleston Editions sì tẹ̀ ẹ́ jáde.[12][13]

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. Murua, James (8 August 2019). "Ayobami Adebayo is 9mobile Prize for Literature 2017 winner". James Murua's Literature Blog. African Literary Podcast. Archived from the original on 14 August 2019. Retrieved 14 August 2019. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. 1 2 Ndeche, Chidirim (10 December 2017). "The Future Awards Africa 2017: Full List Of Winners". The Guardian (Lagos, Nigeria). https://guardian.ng/life/whatsnew/the-future-awards-africa-2017-full-list-of-winners/.
  3. Comerford, Ruth (23 April 2021). Canongate acquires latest from 'rising global star' Adébáyọ̀. https://www.thebookseller.com/news/canongate-acquires-rising-global-star-ay-b-mi-ad-b-y-s-latest-novel-1256488.
  4. "Nigerian Author Ayòbámi Adébáyò: 'I Don't Want To Be Read For Some Kind Of Anthropology". The Liberation News Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2023-01-22. Retrieved 2026-03-20.
  5. Cain, Sian; Claire Armitstead; produced by Susannah Tresilian (14 March 2017). "Baileys longlist author Ayòbámi Adébáyò, and London book fair – books podcast" (in en-GB) (podcast). The Guardian. ISSN 0261-3077. https://www.theguardian.com/books/audio/2017/mar/14/baileys-ayobami-adebayo-london-book-fair-podcast.
  6. Popescu, Lucy (26 February 2023). "A Spell of Good Things by Ayòbámi Adébáyò review – a blistering indictment of the abuse of power". The Observer. https://www.theguardian.com/books/2023/feb/26/a-spell-of-good-things-by-ayobami-adebayo-review-a-blistering-indictment-of-the-abuse-of-power.
  7. "The UEA Creative Writing International Scholarships - UEA". www.uea.ac.uk (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 3 April 2017.
  8. "Konversations with Karibee – Ayọ̀bámi Adébáyọ̀". Karibee Books (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 24 May 2017. Archived from the original on 23 October 2021. Retrieved 27 May 2020. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  9. Ogunlesi, Tolu (6 October 2015). "A new chapter in Nigeria's literature". Financial Times. Retrieved 3 April 2017.
  10. Angelini, Francesca (19 March 2017). "Books: Stay With Me by Ayobami Adebayo" (in en). The Times. https://www.thetimes.com/culture/books/article/books-stay-with-me-by-ayobami-adebayo-k8zm2mdn7.
  11. Kakutani, Michiko (24 July 2017), Portrait of a Nigerian Marriage in a Heartbreaking Debut Novel (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì), ISSN 0362-4331, retrieved 31 March 2026
  12. "Reste avec moi". Editions Charleston (in Èdè Faransé). Retrieved 2025-10-03.
  13. Ahmad, Aamina (5 February 2023). "A Novelist Bridges the Class Divide in Contemporary Nigeria". The New York Times. https://www.nytimes.com/2023/02/05/books/review/ayobami-adebayo-a-spell-of-good-things.html.
  14. Williams, Megan (3 April 2017). "Women's Prize for Fiction 2017 shortlist announced, with settings ranging from 19th century Kentucky to 1980s Nigeria". The Independent (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2 March 2021.
  15. Anderson, Porter (19 March 2018). "Wellcome Book Prize's 2018 Shortlist: Five of Six Titles Are by Women". Publishing Perspectives (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 15 June 2018.
  16. Malec, Jennifer (8 August 2019), "Ayọ̀bámi Adébáyọ̀ announced as winner of 9mobile Prize for Literature for her debut novel Stay With Me", Johannesburg Review of Books.
  17. Nwakunor, Gregory Austin (11 August 2019), "Ayobami Adebayo wins 2018 9mobile prize", The Guardian (Nigeria).
  18. https://cene.lacenelitteraire.com/prix-litteraire-les-afriques/prix-les-afriques-2020/
  19. Oury, Antoine (30 November 2020). "Ayobami Adebayo lauréate du Prix Les Afriques 2020 pour Reste avec moi". ActuaLitté.com (in Èdè Faransé). Retrieved 2 March 2021.
  20. Murua, James (28 November 2020). "Ayobami Adebayo's 'Reste Avec Moi' is Prix Les Afriques 2020 winner". James Murua's African Literature Blog (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 18 February 2021. Retrieved 2 March 2021. Unknown parameter |url-status= ignored (help)