Búrẹ́dì Agége
Ìrísí
Agege bread being sold by a vendor in Nigeria. | |
| Type | Bread |
|---|---|
| Course | Street food |
| Place of origin | Nigeria |
| Associated national cuisine | Nigeria |
| Main ingredients | wheat flour, yeast, sugar |
Àdàkọ:Wikibooks-inline
| |
Búrẹ́dì Agege, jẹ́ búrẹ́dì tí ó dùn, tó ní ìwúkàrà, tí ó sì funfun, láti Agege ní Ìpínlẹ̀ Lagos, Nàìjíríà. Nínú agolo onígunmẹ́rin èyí tí ó jọ ti búrẹ́dì Pullman ni wọ́n ti máa ń ṣe búrẹ́dì Agege. Láti Agége sí Ìpínlẹ̀ Lagos, sí àgbègbè mìíràn káàkiri orílẹ̀-èdè ni búrẹ́dì Agége yìí ti jẹ́ mímọ̀; àwọn tí ń kiri máa ń tà á, bẹ́ẹ̀ sì ni wọ́n máa ń tà á lọ́nà.
Òǹkọ̀wé oúnjẹ àti ìtàn Ozoz Sokoh ni ó ṣiṣẹ́ ìwádìí, tí ó sì gbé ìwé-àpámọ́ kan kalẹ̀ lórí búrẹ́dì Agege, "Níbo ni Búrẹ́dì Agege Ti Wá?"[1] Amos Shackleford, ẹni tí ó wá láti orílẹ̀-èdè Jamaica wá sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ni wọ́n fún ní ẹ̀yẹ pé ó ṣẹ̀dá búrẹ́dì náà ni Agege ni ọdún 1921, lẹ́yìn tí ó fi iṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú Nigerian Railway Corporation sílẹ̀ láti di ólùfọ́rẹ́.[2]

Tún Wo
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Àwọn Ìtọ́kási
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Where Did Agege Bread Come From?". For Africans. 14 May 2019. Archived from the original on 11 October 2021. Retrieved 9 March 2021 – via YouTube. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Nneka M. Okona (August 23, 2023). "Understanding My Nigerian Father Through His Love of Agege Bread". Conde Nast Traveler.