Babangida Alhassan Abdullahi
Ìrísí
Babangida Alhassan Abdullahi jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà. O jẹ ọmọ ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú àgbègbè Dala ni ilé igbimọ aṣòfin apapọ orílè-èdè Nàìjíríà. Wọn bí ní ọjọ́ kẹtàdínlogbon oṣù karùn-ún ọdún 1976, o jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Kano. Wọ́ diboyan sì ìle igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà ni ọdún 2019 lábẹ́ ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC).[1][2]
Itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-06.
- ↑ "Legislator Details - ConsTrack Track and Report on Governement Funded Projects in Nigeria". www.constrack.ng. Retrieved 2025-01-06.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
Àwọn ẹ̀ka:
- CS1 Èdè Gẹ̀ẹ́sì-language sources (en)
- All articles with dead external links
- Articles with dead external links from April 2026
- Articles with invalid date parameter in template
- Articles with permanently dead external links
- Living people
- Nigerian political people
- Members of the House of Representatives (Nigeria) from Kano State
- All Progressives Congress members of the House of Representatives (Nigeria)
- 1976 births