Jump to content

Babangida Alhassan Abdullahi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Babangida Alhassan Abdullahi jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà. O jẹ ọmọ ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú àgbègbè Dala ni ilé igbimọ aṣòfin apapọ orílè-èdè Nàìjíríà. Wọn bí ní ọjọ́ kẹtàdínlogbon oṣù karùn-ún ọdún 1976, o jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Kano. Wọ́ diboyan sì ìle igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà ni ọdún 2019 lábẹ́ ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress (APC).[1][2]

  1. "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-06.
  2. "Legislator Details - ConsTrack Track and Report on Governement Funded Projects in Nigeria". www.constrack.ng. Retrieved 2025-01-06.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]