Babatunde Jose
Ìrísí
Alhaji[1] Ismail Babatunde Jose OFR[2] (tí wọ́n bí sí ìlú Èkó ní ọjọ́ kẹtàlá oṣù Kejìlá ọdún 1925, ó kú ní ọjọ́ kejì oṣù kẹjọ ọdún 2008[3]) ọ́ jé akọ̀rọ̀yìn àti atúntò ìwé ìròyìn tí Nàìjíríà . Ìwé ìròyìn The Guardian ṣe àpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́bí ògbótagìrì akọ̀rọ̀yìn Nàìjíríà " àti "ọ̀kan lára àwọn ènìyàn jákàn ní ilé ìṣe igbóhùn sàfẹ́fẹ́ tí Nàìjíríà.[4]
Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé ẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Babatunde Jose gba ẹ̀kọ́ rẹ̀ ní ilé ìwé Lagos Government School, Yaba, '' The British pẹ̀lú gẹ́gẹ́bí Babánlá àwọn akọ̀rọ̀yìn ti Nàìjíríà ''. Lagos, Methodist school, Yaba and St Saviour's College.
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Babatunde Jose: Legendary doyen of Nigerian journalism", The Guardian, 25 August 2008
- ↑ "Ismail Babatunde Jose: Newspaper editor who dominated journalism in Nigeria for three decades", The Independent, 25 September 2008
- ↑ "Remembering Alhaji Babatunde Jose (1925-2008)". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2015-08-02. Retrieved 2022-03-07.
- ↑ Daily Times of Nigeria Limited., & Namme, L. N. (1976). P. 92