Jump to content

Basirat Nahibi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́


Basirat Nahibi
Orúkọ mírànBasirat Nahibi-Niasse
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigeria
Iṣẹ́Politician, entrepreneur
OrganizationWomen Advancement for Economic and Leadership in Africa (WAELE)
Political partyAll Progressives Congress

Basirat Nahibi tàbí Basirat Nahibi-Niasse jẹ́ òṣèlú, oníṣòwò àti òṣèlú-bìnrin àkọ́kọ́ to díje fún ipò gómìnà l'órílẹ́-èdè Nigeria. [1][2]

Òun olùdásílẹ̀ Women Advancement for Economic and Leadership in Africa (WAELE);[3][4] ẹgbẹ́ tí kò sì fún èrè jíjẹ tó ń ró àwọn obìnrin ilẹ̀ adúláwò lágbára nínú ọ̀rọ̀ ètò ajé àti ìṣèlú, tí ó sì máa ń jẹ́ kí wọ́n kópa nínú ìpẹ̀tùsáwọ̀ káàkiri orílẹ̀-èdè méjìlẹ̀láàádọ́ta (52) ní Africa. Bẹ́ẹ̀ náà ló jẹ́ ọ̀kan lára àwọn olùdásílẹ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress.[5]

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "First Female – firstnigerian". Google. Retrieved 12 May 2019. 
  2. Alqali, Adam (25 February 2019). "INTERVIEW: "WAELE AFRICA raising the voices of African women, through economic empowerment" – Basirat Nahibi-Niasse". African Newspage. Retrieved 12 May 2019. 
  3. Newspapers, BluePrint (10 May 2019). "Ondo women group empowers widows with N2m". Blueprint. Retrieved 12 May 2019. 
  4. "High turnout at Aso Rock polling units, Kyari hails INEC". The Sun Nigeria. 23 February 2019. Retrieved 12 May 2019. 
  5. "Leadership Newspaper – Nigerian News, Nigeria Newspapers". Leadership Newspaper. Retrieved 12 May 2019.