Bode Thomas

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Oloye Bode Thomas (ti a bi ni ojo ketalelogun osu kokanla odun 1919 ti o sin di oloogbe ni odun 1953) je agbejoro, oloselu, ati agba-oje agbasaga omo Yoruba lati ilu Oyo lorile-ede Naijiria.[1] O pegede gege bi minisita nigba isejoba awon oyinbo ti n sakoso orile-ede Naijiria ki Naijiria to gba ominira lodun 1960. Oun kan naa ni Minisita igbokegbodo oko akoko lorile-ede Naijiria leyin ti Naijiria gba ominira.[2]

Awon Itokasi




Itokasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Bode Thomas". Wikipedia. 2007-05-29. Retrieved 2019-09-30. 
  2. Ifeoma, Peters (2018-10-18). "Fallen Legal Heroes: Chief Bode Thomas". DNL Legal and Style. Archived from the original on 2019-01-25. Retrieved 2019-09-30.