Bombei Festival
Ìrísí
Bombei Festival (Ọdún iṣu) jẹ́ àjọ̀dún ìkórè ọdọọdún ti àwọn olóyè àti àwọn ènìyàn Ekyem Kofi máa nṣe nítòsí Sekondi ní Ẹkun Ìwọ̀-oòrùn ti Ghana . Oṣù Keje ní wọn máa n ṣe ayẹyẹ náà. [1] [2] [3] [4] [5]
Àwọn ayẹyẹ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Lakokò àjọ̀dún, wọn a máa ṣe ìtẹ́wọ́gbà àwọn àlejò láti pin ounjẹ àti ohun mímu. Àwọn ènìyàn gbé asọ ìbílẹ̀ wọ̀, durbar àwọn ìjòyè si wà. Ijó àti ìlù tún wà. [6]
Pàtàkì
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Wọn a máa ṣe ayẹyẹ yíì láti sàmìsí iṣẹlẹ ti o wáyé ni ìṣáájú. [7]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ https://touringghana.com/festivals/
- ↑ "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2020-08-15. Retrieved 2025-10-07.
- ↑ http://ghanareview.com/festivals2.html
- ↑ https://tourghana.com/ghana-festivals/
- ↑ https://web.archive.org/web/20210118192700/http://www.slutchtours.com/?page_id=21
- ↑ "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2020-09-26. Retrieved 2025-10-07.
- ↑ "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2020-08-15. Retrieved 2025-10-07.