Jump to content

Bombei Festival

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Bombei Festival (Ọdún iṣu) jẹ́ àjọ̀dún ìkórè ọdọọdún ti àwọn olóyè àti àwọn ènìyàn Ekyem Kofi máa nṣe nítòsí Sekondi ní Ẹkun Ìwọ̀-oòrùn ti Ghana . Oṣù Keje ní wọn máa n ṣe ayẹyẹ náà. [1] [2] [3] [4] [5]

Lakokò àjọ̀dún, wọn a máa ṣe ìtẹ́wọ́gbà àwọn àlejò láti pin ounjẹ àti ohun mímu. Àwọn ènìyàn gbé asọ ìbílẹ̀ wọ̀, durbar àwọn ìjòyè si wà. Ijó àti ìlù tún wà. [6]

Wọn a máa ṣe ayẹyẹ yíì láti sàmìsí iṣẹlẹ ti o wáyé ni ìṣáájú. [7]

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. https://touringghana.com/festivals/
  2. "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2020-08-15. Retrieved 2025-10-07.
  3. http://ghanareview.com/festivals2.html
  4. https://tourghana.com/ghana-festivals/
  5. https://web.archive.org/web/20210118192700/http://www.slutchtours.com/?page_id=21
  6. "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2020-09-26. Retrieved 2025-10-07.
  7. "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2020-08-15. Retrieved 2025-10-07.