Jump to content

Charity Ekezie

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Charity Chiamaka Ekezie
Ọjọ́ìbíNigeria
Iléẹ̀kọ́ gígaNnamdi Azikiwe University
Àdàkọ:Infobox TikTok personality

Charity Ekezie jẹ́ ọmọ ìpínlè Nàìjíríà Nigerian TikToker àti oníròyìn.[1][2][3]

Ayé àti ẹ̀kọ́

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ekezie dàgbà ní Douala, Cameroon, ní ibi tí ó ti lo ìgbà èwe é tí ó sì parí ilé ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ rẹ̀. Ó dé Nàìjíríà ní ọdún 2001 nígbà tí ó wà ní ọmọ ọdún mẹ́wàá.[4]

Ó Gba ìwé èrí ní mass communicationNnamdi [5]Azikiwe University.[1]

Ekezie ṣiṣẹ́ ní ilé iṣẹ́ ìròyìn fún ọdún mẹ́ta àtàbọ̀.[6] ó ní àwọn òwò orí afẹ́fẹ́ èyí tí kò lò láti ọdún.[7]

Ó darapọ̀ mọ́ he TikTok ní ọdún 2020 nítorí pé nǹká ti sú u látàri àìsàn COVID-19 pandemic.[1] fọ́ńrań tí ó kọkọ́ ṣe gbajúmọ̀ nítorípé ó wó aṣọ ìbílẹ̀ orílẹ̀ èdè ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ní Áfíríkà. Nígbà tí ó ń gba àwọn èsì tí kò dára lórí afẹ́fẹ́ ó pinu láti dá wọn lóhùn pẹ̀lú èsí tí kò bójú mú tó.[7][5] Láti ìgbà náà, gbogbo ohun tí Ekezie ń fi sí orí afẹ́fẹ́ ni ó dálé fífi ọ̀rọ̀ ẹ̀gàn ṣe àtúnṣe lórí ọ̀rọ̀ aburú tí wọ́n ń sọ nípa Áfíríkà. Ọ̀kan lára àwọn fọ́ńrán rẹ̀ ń sọ fún àwọn òǹwòran pé àwọn ọmọ Áfríkà ń mu it ẹnu nítorí àì sí omi nígbàtí wọ́n mú ike omi lọ́wọ́;[1][4][5] nínu fọ́ńrán mìíràn ó ń sọ fún àwọn òǹwòran rẹ̀ pé Áfíríkà jẹ́ orílè èdè tí Wakanda jẹ́ olú ìlú rẹ̀.[8] Ekezie tún sọ̀rọ̀ sí TikTok pé kò gbé ètò fífún àwọn tí ó ń ṣe fọ́ńrán lábẹ́ wọn ní owó dé ọ̀dọ àwọn ọmọ Áfríkà, ìtunmọ̀ Ni pé àwọn ọmọ Áfríkà tí ó ń ṣe TikTok kò le rí owó gbà láti inú fọ́ńrán tí wọ́n ń gbé jáde.

Ní ọdún 2023, 60% nínú àwọn olólùfẹ́ Ekezie wà ní United States.[1] ní oṣù kéje ọdún 2022, Ekezie ní olólùfẹ́ tó tó mílíọ̀nù 1.2; ní oṣù kejì odún 2023 ó di mílíọ̀nù méjì.[9][10]

Ekezie ti sọ pé òun á padà sí iṣẹ́ oníròyìn ní ọjọ́ iwájú.[7]

Ní ọjọ́ kejìlá ọdún 2022, NPR ka Ekezie gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan lára àwọn tí ó gbajúmọ̀.[2]

Ní oṣù kínní ọdún 2023, Ekezie di gbajúmọ̀ fún TikTok gẹ́gẹ́ bí eni tó ṣe fọ́ńrán jù fún ẹ̀bùn 2022 Sub-Saharan ti Áfíríkà [11]

Ekezie dánmọ́rán nínu èdè gẹ̀ẹ́sì English àti faransé French. Ó ní àbúrò ọkùnrin méjì.[1] ó jìyà lọ́wọ́ ìfìyàjẹni bullying, ó sì ti ní ìbẹ̀rù anxiety látàrí ìfìyàjẹni náà.[7]

Ní ọdún 2022, ó ń gbé ní Abuja, ní Nàìjíría.[4]

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. 1 2 3 4 5 6 Thomas-Odia, Ijeoma (28 January 2023). "Charity Ekezie: I never experienced racism until I joined Tiktok". The Guardian Nigeria News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 11 April 2023.
  2. 1 2 Barnhart, Max; Mitre, Estefania (19 December 2022). "Popular global TikToks of 2022: Bad Bunny leads the fluffle!". NPR. https://www.npr.org/sections/goatsandsoda/2022/12/19/1143630317/popular-global-tiktoks-of-2022-bad-bunny-leads-the-fluffle.
  3. Johnson, Sarah (4 June 2024). "'Africa has zero PR in the west': the Nigerian influencer using sarcasm on the clueless" (in en-GB). The Guardian. ISSN 0261-3077. https://www.theguardian.com/global-development/article/2024/jun/04/do-you-have-water-in-africa-charity-ekezie-nigerian-influencer.
  4. 1 2 3 Cheong, Charissa. "As a TikToker living in Nigeria, I was constantly exposed to ignorant comments. Now I use humor to show my followers how wrong they are about life in Africa.". Insider (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 11 April 2023.
  5. 1 2 3 "The Cultural Frontline - How is TikTok changing culture? - BBC Sounds". www.bbc.co.uk (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 10 September 2022. Retrieved 11 April 2023.
  6. Erro, Carlos Bajo (16 April 2022). "Charity Ekezie: humor y Tik Tok contra los estereotipos sobre África". El País (in Èdè Sípáníìṣì). Retrieved 11 April 2023.
  7. 1 2 3 4 Harun (30 March 2022). "Meet Nigerian TikTok Star Charity Ekezie". Career Fodder (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2 June 2023. Retrieved 11 April 2023.
  8. Williams, Chad (28 April 2022). "WATCH: Nigerian TikTok star uses humour to debunk stereotypes about Africa and trust us, you have to see this". IOL. https://www.iol.co.za/news/africa/watch-nigerian-tiktok-star-uses-humour-to-debunk-stereotypes-about-africa-and-trust-us-you-have-to-see-this-fad9ea02-fd58-4d5d-9605-b9f566e4cc97.
  9. Onibada, Ade (15 July 2022). "African Influencers Hope Khaby Lame's Rise Will Mean That Global Success Is Attainable For More Of Them". BuzzFeed News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 11 April 2023.
  10. Odesomi, Omowumi (21 February 2023). "Biggest Social Media Influencers In Africa". African Leadership Magazine (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 11 April 2023.
  11. "TikTok Unveils The First Creators To Win #TopCreator2022 Awards in Sub-Saharan Africa". The Guardian Nigeria News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 15 January 2023. Archived from the original on 11 April 2023. Retrieved 11 April 2023. Unknown parameter |url-status= ignored (help)