Charity Ekezie
| Charity Chiamaka Ekezie | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | Nigeria |
| Iléẹ̀kọ́ gíga | Nnamdi Azikiwe University |
| Àdàkọ:Infobox TikTok personality | |
Charity Ekezie jẹ́ ọmọ ìpínlè Nàìjíríà Nigerian TikToker àti oníròyìn.[1][2][3]
Ayé àti ẹ̀kọ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ekezie dàgbà ní Douala, Cameroon, ní ibi tí ó ti lo ìgbà èwe é tí ó sì parí ilé ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ rẹ̀. Ó dé Nàìjíríà ní ọdún 2001 nígbà tí ó wà ní ọmọ ọdún mẹ́wàá.[4]
Ó Gba ìwé èrí ní mass communication ní Nnamdi [5]Azikiwe University.[1]
Iṣé
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ekezie ṣiṣẹ́ ní ilé iṣẹ́ ìròyìn fún ọdún mẹ́ta àtàbọ̀.[6] ó ní àwọn òwò orí afẹ́fẹ́ èyí tí kò lò láti ọdún.[7]
Ó darapọ̀ mọ́ he TikTok ní ọdún 2020 nítorí pé nǹká ti sú u látàri àìsàn COVID-19 pandemic.[1] fọ́ńrań tí ó kọkọ́ ṣe gbajúmọ̀ nítorípé ó wó aṣọ ìbílẹ̀ orílẹ̀ èdè ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ní Áfíríkà. Nígbà tí ó ń gba àwọn èsì tí kò dára lórí afẹ́fẹ́ ó pinu láti dá wọn lóhùn pẹ̀lú èsí tí kò bójú mú tó.[7][5] Láti ìgbà náà, gbogbo ohun tí Ekezie ń fi sí orí afẹ́fẹ́ ni ó dálé fífi ọ̀rọ̀ ẹ̀gàn ṣe àtúnṣe lórí ọ̀rọ̀ aburú tí wọ́n ń sọ nípa Áfíríkà. Ọ̀kan lára àwọn fọ́ńrán rẹ̀ ń sọ fún àwọn òǹwòran pé àwọn ọmọ Áfríkà ń mu it ẹnu nítorí àì sí omi nígbàtí wọ́n mú ike omi lọ́wọ́;[1][4][5] nínu fọ́ńrán mìíràn ó ń sọ fún àwọn òǹwòran rẹ̀ pé Áfíríkà jẹ́ orílè èdè tí Wakanda jẹ́ olú ìlú rẹ̀.[8] Ekezie tún sọ̀rọ̀ sí TikTok pé kò gbé ètò fífún àwọn tí ó ń ṣe fọ́ńrán lábẹ́ wọn ní owó dé ọ̀dọ àwọn ọmọ Áfríkà, ìtunmọ̀ Ni pé àwọn ọmọ Áfríkà tí ó ń ṣe TikTok kò le rí owó gbà láti inú fọ́ńrán tí wọ́n ń gbé jáde.
Ní ọdún 2023, 60% nínú àwọn olólùfẹ́ Ekezie wà ní United States.[1] ní oṣù kéje ọdún 2022, Ekezie ní olólùfẹ́ tó tó mílíọ̀nù 1.2; ní oṣù kejì odún 2023 ó di mílíọ̀nù méjì.[9][10]
Ekezie ti sọ pé òun á padà sí iṣẹ́ oníròyìn ní ọjọ́ iwájú.[7]
Ẹ̀bùn
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ní ọjọ́ kejìlá ọdún 2022, NPR ka Ekezie gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan lára àwọn tí ó gbajúmọ̀.[2]
Ní oṣù kínní ọdún 2023, Ekezie di gbajúmọ̀ fún TikTok gẹ́gẹ́ bí eni tó ṣe fọ́ńrán jù fún ẹ̀bùn 2022 Sub-Saharan ti Áfíríkà [11]
Ayé rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ekezie dánmọ́rán nínu èdè gẹ̀ẹ́sì English àti faransé French. Ó ní àbúrò ọkùnrin méjì.[1] ó jìyà lọ́wọ́ ìfìyàjẹni bullying, ó sì ti ní ìbẹ̀rù anxiety látàrí ìfìyàjẹni náà.[7]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- 1 2 3 4 5 6 Thomas-Odia, Ijeoma (28 January 2023). "Charity Ekezie: I never experienced racism until I joined Tiktok". The Guardian Nigeria News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 11 April 2023.
- 1 2 Barnhart, Max; Mitre, Estefania (19 December 2022). "Popular global TikToks of 2022: Bad Bunny leads the fluffle!". NPR. https://www.npr.org/sections/goatsandsoda/2022/12/19/1143630317/popular-global-tiktoks-of-2022-bad-bunny-leads-the-fluffle.
- ↑ Johnson, Sarah (4 June 2024). "'Africa has zero PR in the west': the Nigerian influencer using sarcasm on the clueless" (in en-GB). The Guardian. ISSN 0261-3077. https://www.theguardian.com/global-development/article/2024/jun/04/do-you-have-water-in-africa-charity-ekezie-nigerian-influencer.
- 1 2 3 Cheong, Charissa. "As a TikToker living in Nigeria, I was constantly exposed to ignorant comments. Now I use humor to show my followers how wrong they are about life in Africa.". Insider (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 11 April 2023.
- 1 2 3 "The Cultural Frontline - How is TikTok changing culture? - BBC Sounds". www.bbc.co.uk (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 10 September 2022. Retrieved 11 April 2023.
- ↑ Erro, Carlos Bajo (16 April 2022). "Charity Ekezie: humor y Tik Tok contra los estereotipos sobre África". El País (in Èdè Sípáníìṣì). Retrieved 11 April 2023.
- 1 2 3 4 Harun (30 March 2022). "Meet Nigerian TikTok Star Charity Ekezie". Career Fodder (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2 June 2023. Retrieved 11 April 2023.
- ↑ Williams, Chad (28 April 2022). "WATCH: Nigerian TikTok star uses humour to debunk stereotypes about Africa and trust us, you have to see this". IOL. https://www.iol.co.za/news/africa/watch-nigerian-tiktok-star-uses-humour-to-debunk-stereotypes-about-africa-and-trust-us-you-have-to-see-this-fad9ea02-fd58-4d5d-9605-b9f566e4cc97.
- ↑ Onibada, Ade (15 July 2022). "African Influencers Hope Khaby Lame's Rise Will Mean That Global Success Is Attainable For More Of Them". BuzzFeed News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 11 April 2023.
- ↑ Odesomi, Omowumi (21 February 2023). "Biggest Social Media Influencers In Africa". African Leadership Magazine (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 11 April 2023.
- ↑ "TikTok Unveils The First Creators To Win #TopCreator2022 Awards in Sub-Saharan Africa". The Guardian Nigeria News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 15 January 2023. Archived from the original on 11 April 2023. Retrieved 11 April 2023. Unknown parameter
|url-status=ignored (help)