Chidi Nwaogu
Chidi Nwaogu | |
|---|---|
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | 20 Oṣù Kàrún 1990 Ìpínlẹ̀ Eko, Nàìjíríà |
| Ọmọorílẹ̀-èdè | Ọmọ Orílẹ-èdè Nàìjíríà |
| Education | Fásítì ìlú Eko |
| Occupation | Oníṣòwò |
| Known for | Co-Founder and CEO of Publiseer |
| Awards | Africa's Business Heroes by Jack Ma Foundation |
| Website | nwaogu.com/ |
Chidi Nwaogu tí wọ́n bí ní Ogúnjọ́ oṣù kàrún ọdún 1990 jẹ ọmọ orílẹ-èdè Nàìjíríà [1] ọ̀tajà ìmọ̀-ẹrọ́ ati ìdàgbàsókè sọfitiwia, [2] ti o jẹ ọkan ninu awọn Olùdásílẹ̀ ti Publiseer, ile-iṣẹ àtẹ̀jáde oní nọ́mbà kàn ti o wa nílu Eko . [3] Ṣáájú ki o to ṣẹda Publiseer, o ti ṣẹda ìbẹ̀rẹ̀ ilé-iṣẹ́ méjì ti o si ti ta wọn, [4] èyítí o pẹlú LAGbook, nẹtiwọọki awujọ pẹlu awọn ólùmulò ti o ju mílíọ̀nù kàn lọ, eyiti o ṣẹda ni ọdún 2013. [5]
Ni ọdún 2021, Chidi ri ìdánimọ̀ nipasẹ Jack Ma Foundation gẹgẹbi ọ̀kan nínù Àwọn onísòwò mẹwàá ti o jẹ akíkanjú ni ilẹ̀ Áfríkà [6] ti orúkọ rẹ sí tún jẹyọ jade lori Akojọ Agbara YNaija gẹ́gẹ́bí ọkàn nínú Awọn ọdọ ọgọ́run ti o lágbára jùlọ ní Nàìjíríà. [7]
Ilè iṣẹ Publiseer
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ti a dá silẹ ni ọdún 2017 pẹlu arákùnrin t'in ṣe ìbejì rẹ, Chika, [8] [9] láti rí owó gba látinú iṣẹ́ wọn ní orílẹóso è 100. [10] Ni Oṣu Kẹsan 20a , ilàṣà ẹ ti ṣiṣẹ pẹlu awọn olupilẹṣẹ 8,000 ni Afirika, [11] tó fi mọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ orin Nàìjíríà bíi Erigga ati CDQ . [12] Nípasẹ̀ ìpẹ̀yà pọ̀ pẹ̀lú Google, Publiseer wà ni Nigeria, Kenya, Ghana, South Africa, ati Egipti. [13] Nítorí ounká iwọn akópa tó wà lórí pẹpẹ rẹ̀, a tilo jẹ kiwọn ní, “ọ̀kan nínú àwọn olùtẹ̀jáde oni-nọ́mbà olómìnira tó tóbi jù lọ ní Áfíríkà.”. [14]
Savvy
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Chidi jẹ ọkán nínú àwọn Olùdásílẹ̀ Savvy, eto ti o ṣe ikẹkọ, ṣe atilẹyin, tó sì ń ṣè atìlẹ́yìn fún àwọn oníṣòwò tuntun. [15] Ni ajọṣepọ pẹlu Ẹgbẹ Aladani Kenya, Savvy ti kọ awọn oniṣòwo ẹgbẹrun lọnà méje àbọ̀ 7,500. [16] Wọn dá Savvy sílẹ ni ọdun 2020, ati pe wọn ń ṣe e níta ayélujára ní èdè tó tó ọgọrùn [17] ati pe on ri ìrànwọ owó nipasẹ Ẹgbẹ Ibaraẹnisọrọ Kariaye ati Ọfiisi Ajo Agbaye fun Ifowosowopo South-South . [18]
LAGbook
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]LAGbook jẹ iṣẹ nẹtiwọọki awujọ lati orilẹ-ede Naijiria, eyiti o dojukọ awọn ọdọ ti o wa laarin ọjọ-ori méjìdínlógún sí ọgbọ̀n, ti n wa lati ri awọn ọrẹ lori ayélujára. [19] Pẹlu àwọn ìforúkọsílẹ titun bí ẹgbẹ̀rún lọnà mẹ́rin lójoojúmọ́, [20] nẹtiwọki awujọ náà tun ni awọn ólùmulò lati India, Germany, Canada, ati Spain. [19] Ti a dá silẹ ni ọdun 2010 láti ọwọ́ Chidi ati ọmọ ìyà rẹ, Chika, lákokò ti wọn n kọ ẹkọ ni Fasiti ìlú Eko, lọwọ [21] LAGbook rí awọn olumulo mílíọ̀nù kan ti o forukọsilẹ laarin ọdun mẹta. [22]
Àmì ẹ̀yẹ ati ìdánimọ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ni ọdún 2020, Chidi gba Ẹbun Iṣowo ìṣíwá nipasẹ Ẹka ìjọba àpapọ ti Ilu ajeji ti Switzerland . [23] Awọn ami-ẹri miiran pẹlu Aami Eye Iṣowo Afirika nipasẹ Bank of Africa, [24] Roddenberry Foundation Catalyst Award, Aami Eye Iṣọkan Telecommunication International fún Ẹ̀bùn ìṣẹ̀dá Káríayé, [25] ati Ààmì Eye Gbígbà wájú Ọgọrun Àgbáyé fun ẹ̀bùn Asíwájú.
Ni ọdún 2025, Chidi gbà idanimọ nipasẹ Legit.ng gẹgẹbi ọkan ninu "Awọn oludokoowo ọdọ Nàìjíríà ti yoo ṣe dáadáa ni ọdún 2025", [26] ati ni ọdún 2022, gẹgẹbi ọkan ninu "àwọn Mejo ènìyàn oníṣòwò ti o tayọ jùlọ ni Nàìjíríà". [27]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ https://opportunitydesk.org/2019/06/01/chidi-nwaogu-from-nigeria-od-ypom-june-2019/
- ↑ "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2024-11-05. Retrieved 2025-08-16.
- ↑ https://ventureburn.com/2019/02/publiseer-startup-world-cup-nigeria/
- ↑ https://www.seedstars.com/content-hub/life/how-one-platform-helps-african-artists-pave-their-way-success/
- ↑ https://www.thisdaylive.com/index.php/2021/11/29/young-nigerian-receives-africas-business-heroes-prize-by-chinese-billionaire-jack-ma
- ↑ https://africa.businessinsider.com/local/leaders/10-entrepreneurs-from-nigeria-kenya-and-5-other-countries-announced-as-the-2021/57s8eky
- ↑ https://ynaija.com/ynaijapowerlist2021-davido-ola-brown-tacha-dare-adekoya-tunde-ednut-listed-among-most-powerful-young-nigerians/
- ↑ https://techpoint.africa/2018/02/22/publiseer-hbs-new-venture-competition/
- ↑ https://publishingperspectives.com/2019/06/publiseer-entrepreneurs-chidi-and-chika-nwaogu-emerging-markets-ipa-nairobi-2019-seminar/
- ↑ https://www.musicinafrica.net/fr/node/36304
- ↑ https://innovation-village.com/african-digital-content-distribution-platfrom-publiseers-secures-distribution-partnership-with-citeste-ro/
- ↑ https://venturesafrica.com/brothers-chidi-and-chika-nwaogu-founders-of-publiseer-are-on-a-mission-to-take-over-africas-digital-publishing-space/
- ↑ https://itweb.africa/content/Pero3MZxPOYvQb6m
- ↑ https://web.archive.org/web/20180314042812/http://www.konbini.com/ng/lifestyle/nigerian-startup-creatives-digitally-publish-distribute-work/
- ↑ https://www.legit.ng/business-economy/technology/1499493-technigerian-tech-entrepreneur-chidi-nwaogu-receives-global-award-education-innovation/
- ↑ https://ventureburn.com/2022/09/savvy-to-train-1-000-start-up-founders-in-kenya/
- ↑ https://ventureburn.com/2021/03/fellowship-programme-for-entrepreneurs-expands/
- ↑ https://www.legit.ng/business-economy/technology/1446195-young-nigerian-secures-funding-from-the-international-telecommunication-union-and-the-united-nations/
- 1 2 https://htxt.co.za/2014/02/17/top-african-social-networks-probably-dont-know/
- ↑ https://www.goodchristianchat.com/top-5-african-social-networks/
- ↑ https://venturesafrica.com/lagbook-partners-south-africa-umuntu-media/
- ↑ https://www.itnewsafrica.com/2019/09/nigerian-entrepreneur-wins-first-prize-at-the-africa-35-35-awards/
- ↑ https://cioafrica.co/chidi-nwaogu-wins-migration-entrepreneurship-prize-by-swiss-government/
- ↑ "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2025-01-20. Retrieved 2025-08-16.
- ↑ https://meaningful.business/team/chidi-nwaogu/
- ↑ https://www.legit.ng/business-economy/economy/1633965-nelson-elemi-young-investors-shape2025/
- ↑ https://www.legit.ng/business-economy/technology/1509991-legitngs-outstanding-business-personalities-nigeria-startups/