Dadasare Abdullahi
Maimuna Dada-Sare Abdullahi ỌJỌ́ AJÉ (1918–1984) o jẹ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó sí jẹ ònkọ̀wé, nọọsi, olùkọ́ni àti akọ̀ròyìn tí ìran tí Fúláni. Ìbáṣepọ̀ awuyewuye rẹ̀ pẹ̀lú Rupert East, tí ó jẹ́ akọ̀wé àti onímọ̀-ẹ̀kọ́ tí èdè gẹ̀ẹ́sì, tako àṣà àti èròngbà àwùjọ tí Colonial Northern Nigeria.
Ìgbésí ayé
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Dadasare (ọ̀rọ̀ Fulfulde fún ìyàwó tàbí ìyá ilé) wọn bí sínu ẹbí tí óní àǹfàání díẹ̀ ní Gola ní agbègbè Bajama tí Adamawa. Ní ìgbà tí ó sì jẹ́ ọmọ kékeré, ẹbí rè tímọ́tímọ́ kó lọ sí Jambutu tí ohùn náà wà nì Adamawa.Nínu ìwé rẹ It Can Now Be Told, ó kọ bí ìgbà èwe rẹ̀ ṣe kún fún isé àti ìdùnnú kí ó tó di ìgbà ìjínigbé rẹ.[1]
Ìjínigbé
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ní gbà ìrìn àjò kàn ní 1929 lọ sí Gola pẹ̀lú ẹbí kan, wọ́n ji gbé nípa àṣẹ British colonial district officer tí ó nífẹẹ ọmọ obìnrin Fúlàní. Ìbátan àgbà l'ọkunrin rẹ, tí ó ba rí ìrìn àjò ló ṣì Gola, wà lára ètò àti ìmúsẹ ìjínigbé rẹ ó jẹ́ ọmọ odún mọ́kànlá ní ìgbà náà. Ọ́físà náà pàṣẹ títò àwọn ọmọdé binrín tí Fúlàní mẹ́ta àìbàlágà tí wọ́n jí gbé, nínú wọ́n ní ó ti mú Dadasare.[2]
References
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Abdullahi, Dadasare (2019). It Can Now Be Told: The Autobiography of the First Female Writer in Colonial Northern Nigeria (1st ed.). Informart Publishers. pp. 13–22. ISBN 9789789713738.
- ↑ Ochonu, Moses E. (5 April 2022) (in en). Emirs in London: Subaltern Travel and Nigeria's Modernity. Indiana University Press. pp. 322–330. ISBN 978-0-253-05914-7. https://books.google.com/books?id=nsRLEAAAQBAJ.