Jump to content

Dadasare Abdullahi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Maimuna Dada-Sare Abdullahi ỌJỌ́ AJÉ (1918–1984) o jẹ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó sí jẹ ònkọ̀wé, nọọsi, olùkọ́ni àti akọ̀ròyìn tí ìran tí Fúláni. Ìbáṣepọ̀ awuyewuye rẹ̀ pẹ̀lú Rupert East, tí ó jẹ́ akọ̀wé àti onímọ̀-ẹ̀kọ́ tí èdè gẹ̀ẹ́sì, tako àṣà àti èròngbà àwùjọ tí Colonial Northern Nigeria.

Dadasare (ọ̀rọ̀ Fulfulde fún ìyàwó tàbí ìyá ilé) wọn bí sínu ẹbí tí óní àǹfàání díẹ̀ ní Gola ní agbègbè Bajama tí Adamawa. Ní ìgbà tí ó sì jẹ́ ọmọ kékeré, ẹbí rè tímọ́tímọ́ kó lọ sí Jambutu tí ohùn náà wà nì Adamawa.Nínu ìwé rẹ It Can Now Be Told, ó kọ bí ìgbà èwe rẹ̀ ṣe kún fún isé àti ìdùnnú kí ó tó di ìgbà ìjínigbé rẹ.[1]

Ní gbà ìrìn àjò kàn ní 1929 lọ sí Gola pẹ̀lú ẹbí kan, wọ́n ji gbé nípa àṣẹ British colonial district officer tí ó nífẹẹ ọmọ obìnrin Fúlàní. Ìbátan àgbà l'ọkunrin rẹ, tí ó ba rí ìrìn àjò ló ṣì Gola, wà lára ètò àti ìmúsẹ ìjínigbé rẹ ó jẹ́ ọmọ odún mọ́kànlá ní ìgbà náà. Ọ́físà náà pàṣẹ títò àwọn ọmọdé binrín tí Fúlàní mẹ́ta àìbàlágà tí wọ́n jí gbé, nínú wọ́n ní ó ti mú Dadasare.[2]

  1. Abdullahi, Dadasare (2019). It Can Now Be Told: The Autobiography of the First Female Writer in Colonial Northern Nigeria (1st ed.). Informart Publishers. pp. 13–22. ISBN 9789789713738.
  2. Ochonu, Moses E. (5 April 2022) (in en). Emirs in London: Subaltern Travel and Nigeria's Modernity. Indiana University Press. pp. 322–330. ISBN 978-0-253-05914-7. https://books.google.com/books?id=nsRLEAAAQBAJ.