Jump to content

Donny Crown

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Donny Crown
Ọjọ́ìbí30 Oṣù Kẹrin 1993 (1993-04-30) (ọmọ ọdún 33)
Ibadan, Nigeria
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigerian
Ẹ̀kọ́Adekunle Ajasin University
Iṣẹ́singer, songwriter, music executive
Ìgbà iṣẹ́2012Àdàkọ:Endashpresent
Gbajúmọ̀ fúnMusic

Ishola Abdul Rasaq Adedoyin (tí wọ́n bí ní ọjọ́ ọgbọ̀n oṣù Kẹrin ọdún 1993), tí a mọ̀ sí Donny Crown, jẹ́ olórin ní ilẹ̀ Nàìjíríà, akọrin àti aṣagbátẹrù orin. Lẹ̀yìn tó farahàn nínú orin “Money for Hand” tí Mohbad kọ lọ́ ṣẹ̀ di gbajúmọ̀ olórin.[1][2]

Ní oṣù Kìíní ọdún 2024, ó ṣe àgbéjáde orin kan lẹ́yìn “Money for Hand”, tí àkọ́lé rẹ̀ ń jẹ́ “Grace”, níbi tí ó ti ṣàfihàn olórinBadboyTimz.[3]

Ìgbésí ayé àti ìbẹ̀rẹ̀ ẹ̀kọ́ rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Donny Crown wá láti agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ Lagelu ní ìlú Ibadan, ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.

Donny Crown lọ sí ilé-ìwé Fountain International níbi tí ó ti parí ẹ̀kọ́ girama rẹ̀, tí ó sì wọlé sí Fasiti Adekunle Ajasin, níbi tí ó tí gboyè ẹ̀kọ́ nínú ìmọ̀ Applied Mathematics.[4]

Iṣẹ́ tó yàn láàyò

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Donny Crown bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ orin kíkọ ní ọdún 2012, pẹ̀lú kíkọ orin àwọn olórin ní àrà ọ̀tọ̀.

Ní ọdún 2022, Donny Crown ṣe àgbéjáde orin àdákọ kan, tí àkọ́lé rẹ̀ jé “feeling good” pẹ̀lú “M.E.D.E”.[5]


Ní ọdún 2023, ó ṣe ìdásílẹ̀ MEDE,[6] èyí tó jẹ́ ilé-iṣẹ́ tó ń rí sí ìtọ́nisọ́nà àwọn olórin tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ń dìde bọ̀.[7]

Ní oṣù Kẹsàn-án ọdún 2023, Donny Crown ṣe àgbéjáde orin “Money for Hand” níbi tí ó ti ṣàfihàn Mohbad. Orin náà ti tu silẹ lẹhin ti iku ni ọsẹ diẹ ṣaaju iku iku MohBad iku iku Mohbad ni Oṣu Kẹsan ọdun 2023, o tun ṣetọrẹ awọn ẹtọ ọba lati awọn ṣiṣan si ọmọ MohBad gẹgẹbi iṣafihan iṣe oore.

Ni Oṣu Kini ọdun 2024, Donny Crown ṣe ifilọlẹ “Grace” ti o nfihan akọrin Naijiria ati akọrin Bad Boy Timz .

  • Money for Hand (pẹ̀lú MohBad )[8]
  • Grace (pẹ̀lú Bad Boy Timz)[9]
  • Feeling Good (pẹ̀lú Lissy B ati Shola Tyson)

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "Donny Crown releases ‘Money for Hand’ featuring Mohbad". SundiataPost. Retrieved 2024-09-03.
  2. "Singer Donny Crown striving for success in music industry - Daily Trust". dailytrust.com. August 28, 2024. Archived from the original on January 16, 2025. Retrieved January 16, 2025.
  3. Okogba, Emmanuel (7 February 2024). "Singer, Donny Crown features Bad Boy Timz in new Afrobeats single 'Grace'".
  4. Emmason, Jerry. "Singer, Donny Crown Speaks On Goals In Music Industry". Leadership News. Retrieved 2024-09-06.
  5. "M.E.D.E Drops 'Feeling Good' Featuring Lissy Bee, Donny Crown & Shola Tyson | LISTEN!". NotjustOk.
  6. "Donny Crown Launches Mede Digital – THISDAYLIVE". www.thisdaylive.com.
  7. "Donny Crown, visionary shaping entertainment scene". The Nation Newspaper. Retrieved 2023-08-07.
  8. "Donny Crown releases ‘Money for Hand’ featuring Mohbad". SundiataPost. Retrieved 2024-09-03.
  9. TALI, SELORM. "Donny Crown joins forces with Bad Boy Timz for new single 'Grace'". Pulse Ghana. Retrieved 2024-02-01.