Doyin Kukoyi
Ìrísí
Doyin Kukoyi (tí wọ́n bí lọ́jọ́ 25, April[1]) jẹ́ òṣèré sinimá àgbéléwò, agbóhùnsá-fẹ́fẹ́ àti olóòtú agbóhùnsá-fẹ́fẹ́ ọmọ Nigeria[2][3] Ó di gbajúmọ̀ ṣíṣe olóòtú ètò kan tí wọ́n pè ní Gbajúmọ̀ Òṣèré lórí ẹ̀rọ telifisan.[4]
Kòbákùngbé
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Lọ́dún 2022, wọn gbé pò yẹnu pé Doyin Kukoyi ni ìfẹ́ ìkọ̀kọ̀ pẹ̀lú gbajúmọ̀ òṣèré-kùnrin Taiwo Hassan tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ògògó. Kódà, ìròyìn àhesọ náà sọ pé wọ́n ṣe ìgbéyàwó ìkọ̀kọ̀: ṣùgbọ́n gbogbo èyí ni Doyin sẹ́ pátápátá.[5][6][7]
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Adedoyin Kukoyi Biography". 360dopes. 2018-12-02. Retrieved 2025-10-25.
- ↑ Omogbolagun, Tope (2020-02-28). "Before Stardom With...with Doyin kukoyi (gbajumo Osere)". Punch Newspapers. Retrieved 2025-10-25.
- ↑ Apanpa, Olaniyi (2025-09-12). ""Having an affair with Ogogo?" Actress Doyin Kukoyi finally clears air". Legit.ng - Nigeria news. Retrieved 2025-10-25.
- ↑ Koiki, Olusegun (2025-08-11). "Gbajumo Osere: From Disastrous Debut To Becoming Household Talk Show On Tv – Kukoyi". Independent Newspaper Nigeria. Retrieved 2025-10-25.
- ↑ "Breaking News, Nigerian News, Paris2024, EndBadGovernanceInNigeria, Protest & Top Stories". PMNews Nigeria. 2025-09-10. Retrieved 2025-10-25.
- ↑ Onikoyi, Ayo (2025-09-14). "Doyin Kukoyi clears the air on Ogogo's marriage rumour". Vanguard News. Retrieved 2025-10-25.
- ↑ Fasan, Yewande (2025-09-10). "Doyin Kukoyi debunks marriage rumours with Ogogo". The Nation Newspaper. Retrieved 2025-10-25.