Khalil Nur Khalil
| Khalil Nur Khalil | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | 4 Oṣù Kọkànlá 1992 Kaduna, Nigeria |
| Ọmọ orílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Iléẹ̀kọ́ gíga | |
| Iṣẹ́ |
|
| Office |
|
Khalil Nur Khalil Je onímò ètò ìṣirò ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà. Gómìnà ìpínlè Kaduna Mallam Nasir Ahmad el-Rufai yàn gẹgẹbi olùdarí fún ètò oníṣòwò ni ọdun 2019. Ni ọdun, 2023 wọn yàn si ipò olú bá dá mọnran nípa ètò ọ̀rọ̀ ajé si gómìnà ìpínlè Katsina Malam Dikko Umar Radda.[1]
Igbesi aye ìbéèrè
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Àbí Khalil ni ìpínlè Kaduna o kàwé ní Glenalmond College in Perth, Scotland ni ibiti oti kàwé gboyè nípa ètò oro-aje ni ilé-ẹ̀kọ́ gíga Eastern Mediterranean University, Famagusta, North Cyprus
Ìṣe
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Khalil bẹ̀rẹ̀ Ìṣe ni ọdun 2018, ni ilé Ìṣe ìjọba ìpínlè Kaduna Investment Promotion Agency (KADIPA) gẹgẹbi oluranlowo sì Ádárì ètò ìpolongo ni ọdun 2018, ni ọdun 2021, wọn yàn gẹgẹbi olùdarí àgbà fún eka ìjọba ìpínlè Kaduna fún ètò oro-aje Kaduna Investment Promotion Agency, síwájú àkókò náà wọn ti yàn gẹgẹbi alamojuto Ẹ̀ka náà. Ni ọdun 2023 wọn yàn gẹgẹbi olú bá dá mọnran nípa ètò ọ̀rọ̀ ajé sì gómìnà ìpínlè Katsina.[2]