Jump to content

Enyimba FC

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Enyimba FC
Full nameEnyimba Football Club
Nickname(s)Peoples' Elephant, The Aba Warriors
Founded1976; ọdún 49 sẹ́yìn (1976)
GroundEnyimba International Stadium, Aba, Abia, Nigeria
(Capacity: 16,000)
OwnerAbia State Government
ChairmanNwankwo Kanu
LeagueNigeria Premier Football League
2025–2611th of 20
WebsiteClub home page

Enyimba Football Club, tí a mọ̀ sí Enyimba,jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílè-èdè Nàìjíríàfootball èyítí o wà ní ìlú Aba, tí wọ́n sì ń kópa nínú ìdíje Nigerian Professional Football League. Orúkọ ikọ agbábọ́ọ̀lù náà túmọ̀ sí People's Elephant ní èdè igbó èyítí wọ́n má ń pè ìlú Aba.[1] Wọ́n dá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náà sílẹ̀ ní ọdún 1976, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náà di gbájú gbà já ní ọdún 2000s ikọ̀ náà wá lára àwọn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù tíó ṣe àṣeyọrí jùlọ nínú àwọn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílè-èdè Nàìjíríà ikọ̀ náà tí jáwé olúborí ní è méjì òtọtọ́ nínú ìdíje African Champions League, wọ́n gbà ìfẹ́ ẹ̀yẹ Nigerian championships mẹsan àti ìfẹ́ ẹ̀yẹ Federation Cups ní è mẹ́rin láti ọdún 2001.[2] Àṣeyọrí wọn tó kẹhìn nínú lìgì wáyé ní àkókò ìdíje 2022–23 season.[3]

Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Enyimba ń lo Pápá Ìṣeré Enyimba International tí ó wà ní ìlú Abaìpínlẹ̀ Abia . Wọ́n tún Pápá ìṣeré náà ṣe ní ọdún 2018.

Ìkópa nínú ìdíje CAF

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
2002 – second round
2003champion (Enyimba International F.C. season 2003)
2004champion
2005 – group stage (Top 8)
2006 – group stage (Top 8)
2008 – semi-finals
2011 – semi-finals
2014 – first round
2015 – first round
2016 – group stage (Top 8)
2020 – first round
2010 – second round of 16
2018 – semi-finals
2020 – quarter-finals
2021 – quarter-finals

Àwọn olùkọ́ni ikọ̀ náà nígbà kàn rí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àwọn agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ náà tíó gbajúmò jùlọ

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Stephen Worgu nínú ṣáàtì Enyimba FC ní pápá iṣere Enyimba International Stadium

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "Finidi takes over reins at Aba giants, Enyimba" (in en-GB). Vanguard (Lagos, Nigeria). 2021-09-04. https://www.vanguardngr.com/2021/09/finidi-takes-over-reins-at-aba-giants-enyimba/.
  2. Football, CAF-Confedération Africaine du. "Enyimba set for Raja with eyes firmly on cup prize". CAFOnline.com (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 18 June 2023. Retrieved 2022-05-25. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  3. "Enyimba win record ninth NIgeria Premier League". cafonline.com. Archived from the original on 23 June 2023. Retrieved 23 June 2023. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  4. 1 2 "More new faces for Nigeria". BBC Sport (BBC). 5 April 2002. https://news.bbc.co.uk/sport2/hi/football/africa/1912921.stm.
  5. 1 2 "Urukalo 'loses' Enyimba job". BBC Sport (BBC). 5 August 2004. https://news.bbc.co.uk/sport1/hi/football/africa/3538742.stm.
  6. Copnall, James (12 July 2004). "Enyimba full of confidence". BBC Sport (BBC). https://news.bbc.co.uk/sport2/hi/football/africa/3886907.stm.
  7. 1 2 "Enyimba appoint Cooreman". BBC Sport (BBC). 25 October 2006. https://news.bbc.co.uk/sport2/hi/football/africa/6083662.stm.
  8. Okpara, Christian (12 November 2008). "Why Cooreman left Enyimba, by aide". The Guardian (Nigeria). http://www.ngrguardiannews.com/sports/article03//indexn3_html?pdate=121108&ptitle=Why%20Cooreman%20left%20Enyimba,%20by%20aide&cpdate=121108.
  9. "Enyimba coach Okey Emordi prepared for Wydad Casablanca test". Kick Off. 19 September 2011. Archived from the original on 17 July 2023. Retrieved 16 April 2020. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  10. "Enyimba make Abdu Maikaba their new coach". Kick Off. 3 January 2012. Archived from the original on 17 July 2023. Retrieved 3 January 2021. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  11. "Flying Eagles coach Aigbogun resigns from Enyimba". The Guardian (Lagos, Nigeria). 23 July 2018. https://guardian.ng/sport/flying-eagles-coach-aigbogun-resigns-from-enyimba/.
  12. "Enyimba sacks Usman Abd'Allah as technical adviser". The Guardian (Lagos, Nigeria). 7 January 2020. https://guardian.ng/sport/enyimba-sacks-usman-abdallah-as-technical-adviser/.
  13. Saliu, Mohammed (15 January 2020). "Enyimba's Chief Felix Anyansi reveals plans to make Fatai Osho permanent head coach". Archived from the original on 19 September 2020. Retrieved 16 April 2020. Unknown parameter |url-status= ignored (help)