Enyimba FC
| Full name | Enyimba Football Club | ||
|---|---|---|---|
| Nickname(s) | Peoples' Elephant, The Aba Warriors | ||
| Founded | 1976 | ||
| Ground | Enyimba International Stadium, Aba, Abia, Nigeria (Capacity: 16,000) | ||
| Owner | Abia State Government | ||
| Chairman | Nwankwo Kanu | ||
| League | Nigeria Premier Football League | ||
| 2025–26 | 11th of 20 | ||
| Website | Club home page | ||
|
| |||
Enyimba Football Club, tí a mọ̀ sí Enyimba,jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílè-èdè Nàìjíríàfootball èyítí o wà ní ìlú Aba, tí wọ́n sì ń kópa nínú ìdíje Nigerian Professional Football League. Orúkọ ikọ agbábọ́ọ̀lù náà túmọ̀ sí People's Elephant ní èdè igbó èyítí wọ́n má ń pè ìlú Aba.[1] Wọ́n dá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náà sílẹ̀ ní ọdún 1976, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náà di gbájú gbà já ní ọdún 2000s ikọ̀ náà wá lára àwọn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù tíó ṣe àṣeyọrí jùlọ nínú àwọn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílè-èdè Nàìjíríà ikọ̀ náà tí jáwé olúborí ní è méjì òtọtọ́ nínú ìdíje African Champions League, wọ́n gbà ìfẹ́ ẹ̀yẹ Nigerian championships mẹsan àti ìfẹ́ ẹ̀yẹ Federation Cups ní è mẹ́rin láti ọdún 2001.[2] Àṣeyọrí wọn tó kẹhìn nínú lìgì wáyé ní àkókò ìdíje 2022–23 season.[3]
Pápá ìṣeré
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Enyimba ń lo Pápá Ìṣeré Enyimba International tí ó wà ní ìlú Aba ní ìpínlẹ̀ Abia . Wọ́n tún Pápá ìṣeré náà ṣe ní ọdún 2018.
Ìkópa nínú ìdíje CAF
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- CAF Champions League: ìgbà mẹ́jọ
- CAF Confederation Cup: 3 appearances
Àwọn olùkọ́ni ikọ̀ náà nígbà kàn rí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Kosta Papić (1998–02)[4]
Shaibu Amodu (2002–03)[4]
Kadiri Ikhana (2003–04)[5]
Michael Urukalo (2004)[5]
Okey Emordi (2004–05) [6]
Alphonsus Dike (2005–06)[7]
Maurice Cooreman (Oct 2006 – 9 Feb)[7][8]
Daniel Amokachi (2008)
Augustine Eguavoen (2008–09)
Okey Emordi (Aug 2009 – Nov 2011)[9]
Abdu Maikaba (Nov 2011– Jan 2016)[10]
Paul Aigbogun (Jan 2016 – Jul 2018)[11]
Ali Hanteh (Jul 2018 – Jan 2020)[12]
Fatai Osho (Jan 2020 – 2021)[13]
Finidi George (Sept 2021 – May 2024)
Yemi Daniel Olanrewaju (May 2024 – Dec 2024)
Stanley Azunda Eguma (Jan 2025 – Nov 2025)
Deji Ayeni (Nov 2025 – Jan 2026)
Emmanuel Deutsch (Jan 2026– present)
Àwọn agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ náà tíó gbajúmò jùlọ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Finidi takes over reins at Aba giants, Enyimba" (in en-GB). Vanguard (Lagos, Nigeria). 2021-09-04. https://www.vanguardngr.com/2021/09/finidi-takes-over-reins-at-aba-giants-enyimba/.
- ↑ Football, CAF-Confedération Africaine du. "Enyimba set for Raja with eyes firmly on cup prize". CAFOnline.com (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 18 June 2023. Retrieved 2022-05-25. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Enyimba win record ninth NIgeria Premier League". cafonline.com. Archived from the original on 23 June 2023. Retrieved 23 June 2023. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - 1 2 "More new faces for Nigeria". BBC Sport (BBC). 5 April 2002. https://news.bbc.co.uk/sport2/hi/football/africa/1912921.stm.
- 1 2 "Urukalo 'loses' Enyimba job". BBC Sport (BBC). 5 August 2004. https://news.bbc.co.uk/sport1/hi/football/africa/3538742.stm.
- ↑ Copnall, James (12 July 2004). "Enyimba full of confidence". BBC Sport (BBC). https://news.bbc.co.uk/sport2/hi/football/africa/3886907.stm.
- 1 2 "Enyimba appoint Cooreman". BBC Sport (BBC). 25 October 2006. https://news.bbc.co.uk/sport2/hi/football/africa/6083662.stm.
- ↑ Okpara, Christian (12 November 2008). "Why Cooreman left Enyimba, by aide". The Guardian (Nigeria). http://www.ngrguardiannews.com/sports/article03//indexn3_html?pdate=121108&ptitle=Why%20Cooreman%20left%20Enyimba,%20by%20aide&cpdate=121108.
- ↑ "Enyimba coach Okey Emordi prepared for Wydad Casablanca test". Kick Off. 19 September 2011. Archived from the original on 17 July 2023. Retrieved 16 April 2020. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Enyimba make Abdu Maikaba their new coach". Kick Off. 3 January 2012. Archived from the original on 17 July 2023. Retrieved 3 January 2021. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Flying Eagles coach Aigbogun resigns from Enyimba". The Guardian (Lagos, Nigeria). 23 July 2018. https://guardian.ng/sport/flying-eagles-coach-aigbogun-resigns-from-enyimba/.
- ↑ "Enyimba sacks Usman Abd'Allah as technical adviser". The Guardian (Lagos, Nigeria). 7 January 2020. https://guardian.ng/sport/enyimba-sacks-usman-abdallah-as-technical-adviser/.
- ↑ Saliu, Mohammed (15 January 2020). "Enyimba's Chief Felix Anyansi reveals plans to make Fatai Osho permanent head coach". Archived from the original on 19 September 2020. Retrieved 16 April 2020. Unknown parameter
|url-status=ignored (help)