Ernest ikoli
Ernest Sissei Ikoli (1893–1960) jé omo Nigeria óníròyín atí olòsélú. Òun ní ólùtèjádé akòkó fún Daily Times, ààré fun Nigeria Youth Movement, atí ní odún 1942,osoju Ìpínlé èkó ninu igbìmò asofin.
Ibeere ayé atí isé
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀][edit source] Won bí Ikoli ní Nembe ní Ìpínlé Bayelsa o kèkó ní ilééwè Bonny Government School, Ìpínlé Rivers atí King's College, Èkó .Léyìn tí o parí ní ilééwè King's College, o di olúkóní ní ilééwè nàá - ípò tí o fi sile láti maa se isé óníròyín . Fun asiko dié o sisé pèlú Lagos Weekly Record, ileese to kó sí mò. Òun ní ólùtèjádé akòkó fún Daily Times Nigeria, Èyí tí o di gbígbé jáde ni ósù kéfà odún pèlú Adeyemo Alakija gégé bí alága igbìmò nàá. O pàpà dí olùtéjáde fún African Messenger. Ni odun 1930 o wà lára àwon ólùdásìlé Nigerian Youth Movement o sí pàpà jé aare wón. Laarin odún yii, egbé nàà jijadu agbara pèlú egbé Herbert Macaulay tii se NNDP. Ìgbà re nínú ílésé átèwéjade ko ipa rere lóri gbigba òmínírá Nigeria lòwó àwon oyinbo.ileese nàá wà lára àwon ona tí àwon eniyan Nigeria fi n ba àwon olórí wón soro nìgbà nàá.
Egbé Nigerian Youth Movement
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀][edit source] O bèèrè egbé Nigerian Youth Movement the pèlú àwon omo Nigeria bii Hezekiah Oladipo Davies, James Churchill Vaughan and Oba Samuel Akisanya (aka General Saki). Egbé nàà bèèrè gégé bí Lagos youth movement, wón dá sile Kii o le maa so ainimolara àwon olórí nìpa ètò èkó.Egbe naa bèèrè ní ilu èkó amo nìgbà tí àwon eniyan lati orísirísi ibi wà ní o jé kí o dí Nigeria Youth Movement.Egbe tí o ní ifè orileede lokaan .Nnamdi Azikiwe, dára pò mo wón ní odún 1936.
Ní 1941 Kofo Abayomi, èní ti o jé olórí egbé nàà ní Èkó, Fi ípò sile ní igbìmò asòfin, èyí tí o fa ídíbò.Idibo nàà wáyé laarin àwon omo egbé NYM èyí tí esi rè sope Samuel Akinsanya ní o gbé gba orókè tí Ikoli sí gba ípò keji.Amo, pèlú ìrànlówó H.O.Davies, Obafemi Awolowo,Akintola atí àwon omo egbé mii, igbìmò gbogbogbo, tí o ní ase láti tún idibo nàà se,mu gégé bí omo óyè egbé nàà.Eyi mu ki Akinsanya tete kí kú orire,o sí padà díje gégé bí omo óyè pèlú atileyin Nnamdi Azikiwe,amo ikoli ni o padà bori.Bi Akinsanya se fidiremi ni o jé kí o kúrò ní inu egbé nàà, Èyí ní o mu Azikiwe kúrò tí o sí mu òpòlopò àwon omo egbé wón lo. Èyí ní àwon onwoye kan sope o bèèrè eléyàméyà laarin àwon Igbo, Hausa, Yoruba ní orileede yii atí òkán gbógi nnkan tó fa ija osèlú tí ìlú o fí rogbo.
Bí o tile jè pe o pàdànù ípò rè nínú idibo Mii tí o wáyé ni 1946, wón dá esi rè ru nipa Lilo sí Ilé ejó ,o sí gba ípò rè padà sí igbìmò asòfin. O lo fun idibo gbogbogbo ní odún tó télè amo o yose le kii ètò idibo to bèèrè.
Ní odún 1951, Ikoli, pèlú Awolowo atí àwon isomogbe wón dá Action Group sile, èyí tí o wà láti gbé àsà yórúbá lárúgé ní ibeere òmínírá Nigeria..O dá The Daily Service, èyí tí o polongo nnkan tí egbé nàà gbé dani .Igbejade yii le maa gbajúgbajà to laarin àwon eniyan gusu, atí pe èyí tí kúrò ní oju ona òmínírá tí o wà
Nìgbà tí nkan tí o fí sile le maa gbajúgbajà látàríí eléyàméyà to wáyé nípase òmínírá,a gbodo mo ipa tí o kó ninu òmínírá.Ise átèwéjade re ran Nigeria lòwó láti so Nigeria di olominira.
See also
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- Isaac Adaka Boro
References
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ^ Awo: The Autobiography of Chief Obafemi Awolowo. Cambridge University Press, 1960.
- ^ Toyin Falola, The History of Nigeria, Greenwood Press (30 September 1999). ISBN 0-313-30682-6
- ^
- ^ Austin Uganwa "NIGERIA FOURTH REPUBLIC NATIONAL ASSEMBLY" 2014.
- ^ Awo: The Autobiography of Chief Obafemi Awolowo. Cambridge University Press, 1960. pp. 130-160.
- ^ Al-Bashir, "Documenting Electoral Disputes", Vanguard, Nigeria, 7 August 2003.
- ^ Tekena N Tamuno (1966) Nigeria and Elective Representation 1923−1947, Heinemann, p127
- ^ Toyin Falola and Raphael Chijioke Igbo in the Atlantic World: African Origins and Diasporic Destinations, Indiana University Press, Page 273