Firoze Manji
| Firoze Madatally Manji | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | 1950 (ọmọ ọdún 75–76) Kenya |
| Orílẹ̀-èdè | Kenyan |
| Ẹ̀kọ́ | University of Newcastle upon Tyne; London Hospital Medical College |
| Iléẹ̀kọ́ gíga | University of London |
| Gbajúmọ̀ fún | Editor, publisher and activism |
| Title | Professor |
| Website | darajapress.com/authors/firoze-manji |

Firoze Madatally Manji (born 1950) jẹ ajafitafita fún ètò ọmọ ènìyàn ti o sí jẹ ọmọ orílè-èdè Kenya. O gbà àmì ẹyẹ Nicolás Cristóbal Guillén Batista ni ọdún 2021 fún aṣeyọri ayérayé láti ọwọ àwùjọ Caribbean Philosophical Association.[1]
Ibẹrẹ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Firoze Manji ni wọ́n bí ní ìlú Kenya, sì ìdílé ọmọ orílè-èdè Kenya's ti wón pé ní "Biscuit Baron" Madatally Manji ti ìyàwó rè síń jẹ Fatima.[2] After obtaining a dentistry degree from the University of Newcastle upon Tyne, o bẹrẹ Ìrìnàjò rè gẹ́gẹ́bíi òní ìmò iṣẹgun òyìnbó nípa itọ́jú ẹyin gẹ́gẹ́bíi olùtọ́jú ẹyin àwọn ẹlẹ́wọ̀n àti ṣe iṣẹ́ ní ranpe gẹ́gẹ́bíi olubadamoran fún ìwọlé wode ní ilé ìṣe Hammersmith Law Centre, ní ìlú London. O gbà ìwé ẹ̀rí MSc nípa ìtọ́jú eyín fún gbogbo láti ilé ìwé gíga Yunifásítì Lọndọnu London Hospital Medical College, àti ìwé ẹ̀rí PhD nípa iṣẹgun òyìnbó nílé ẹ̀kọ́ gíga Yunifásítì Lọndọnu bákan náà.
Itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "The Nicolas Cristóbal Guillén Batista Philosophical Literature Prize". Archived from the original on 5 March 2021. Retrieved 22 August 2025.
- ↑ Manji, Madatally, Memoirs of a Biscuit Baron, Nairobi: East African Educational Publishers Ltd, 1995.