Jump to content

Fisayo Soyombo

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Fisáyọ̀ Soyombo tí a bí ní(october 27), je akọ̀ròyìn oníwàádìí ọmọ Nigeria àti ẹni àkọ̀kọ̀ tí ó dá ìwádìí akọ̀ròyìn .[1] ó ti fìgbàkanrí jẹ́ atúmọ̀ ní The Cable.[2] Ó jẹ́ gbajúmọ̀, fún àwọn ohun mìíràn, èyí tí ó jẹ́ akọ̀ròyìn oníwàádìí tí ó lọ ọjọ́ márùún gbáko ní àgọ̀ ọlọ́pàá [3] gẹ́gẹ́ bíi afurasí pẹ̀lú ọjọ́ mẹ́jọ ní ọgbà ẹ̀wọ̀n ti ìkòyí [4] — nítorí àti gbá àwọn tó bá wà nídìí ìwà èrú nínú òfin ìdájọ́ fún àwọn ọ̀daràn ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà mú, lẹ́yìn tí àwọn ìjọba gbìyànjú láti fi kélé òfin gbée.[5] Òun yìí kannáà ni oníròyìn tí ó wa àjígbé ọkọ̀ láti Èkó lọ sí Àbújá. [6]

Ìgbésí ayé àti Ẹ̀kọ́

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Soyombo, ọmọ bíbí Ago-iwoye, Ogun State, tí a bí sí Abeokuta, ìlú ìpínlẹ̀ náà, níbi tí ó ti kẹ́kọ̀ọ́ ní Lawson's Childcare Nursery and Primary School, Labso Nursery and Primary School, àti African Church Grammar School, Ita-Iyalode, Owu.

Ó lo ọdún kan ní Federal University of Agriculture, Alabata, Abeokuta (FUNAAB) ní ọdún 2003, kí ó tó wá tèsíwájú ní Fásitì Ìbàdàn ní 2004 láti kẹ́kọ̀ọ́ ètò ọ̀gbìn, nígbẹ̀yìn-gbẹ́yín ó jáde pẹ̀lú B. Agric. Ní Animal Science.

Iṣẹ́ Tó Yàn Láàyò

Ní ọdún àkọ́kọ́ rẹ̀ ní Fásitì Ìbàdàn, Soyombo darapò mọ́ ẹgbẹ́ atẹ̀ròyìn inú ọgbà, ó darapọ̀ mọ́ Mellanby Hall Press organization (MHPO) àti the Union of Campus Journalists (UCJ).[7] The UCJ nígbà náà ni Kola Tubosun sojú gẹ́gẹ́ bí àrẹ. Lẹ́yìn tí ó gba ìmọ̀ ẹ̀yẹ márùún _ méjì láti UCJ, méjì láti Mellamby Hall Press àti ẹyọ̀kan láti Indy Hall Press, ìkan lára orogún MHPO —UCJ yàn-án gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan lára alábàáṣiṣẹ́ ní ìparì ètò sáà ẹ̀kọ́ rẹ

Guardian, wọ́n fún ùn ní anfààní láti ṣisẹ́ ọjọ́ àìkú lábẹ́ Jahman Anikulapo, láti dángájíá nínú iṣẹ́ rẹ̀. Ní ǹkan bí ọdún mélòó kan sẹ́yìn, Soyombo ní ìbápàdé pẹ̀lú Aníkúlápó gẹ́gẹ́ bí oníròyìn àkọ́kọ́ " èyí sì kó ipa ribiribi nínú iṣẹ́ tó yàn láàyò" .[8]

Soyombo tún ní ájọṣepọ̀ tó dánmọ́rán pẹ̀lú The Guardian — ní ọdún 2006 àti 2009 — ó sì sìn ìlú rere bákan náà gẹ́gẹ́ bí agùn bánirọ̀, èyí tí ó gbe oríyìn fún ọ̀gbẹ́ni Anikulapo àti ògbẹ́ni Martins Oloja, ẹni tí ó jẹ́ olóyè ní Abuja nípasẹ̀ ìwé nígbà náà.

Lẹ́yìn tí ó parí àgùnbánirọ̀ rẹ̀ ọlọ́dún kan ní February 2011 tí àyè iṣẹ́ kò sì ṣí sílẹ̀ ní The Guardian, Soyombo kọ̀wẹ́ fiṣẹ́ sílẹ̀ [9] nítorí Content Watch, ilé epo ìbílẹ̀ content oil and gas magazine tí Taijo Wonukabe dá sílẹ̀ Taiwo Obe sì ń mójú tóo.Soyombo kó lọ sí 'Jobmag', ilé iṣé akọ̀ròyìn ránpẹ́ tí The JobMag Centre gbé jáde, láti ibẹ̀ ní ó ti darapọ̀ mọ́, The Will.

Ní April 2014, ó darapọ̀ mọ́ The Cable, ní èyí tí ó jẹ́ ẹni tó ń mójútó àkójọpọ̀ ìròyìn àti onímọ̀ ìgboùn sílẹ̀ kí ó tó wá gba ìgbéga ní ẹnu iṣẹ́ láàárín oṣù kan tí ó dé bè lẹ́yìn tí ó ti kúrò ní The Cable ní January 2017, ó darapọ̀ mọ́ International Centre for Investigative Reporting (ICIR) gẹ́gẹ́ bíi onímọ̀ nínú rẹ̀, láti ìgbàyí lọ ní ó ti darapọ̀ mọ́ Sahara Reporters gẹ́gẹ́ bí adarí iṣẹ́ láàárín May 2018 títí di June 2019. Bí ó tio jẹ́pé The Cable kéde pé ìgbéjáde rẹ̀ yóò lágbára nínú" iṣẹ́ àti òṣèlú", Soyombo fi ìwádìí akọ̀ròyìn múlẹ̀ nínú ìlànà náà, bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú ìwádìí rẹ̀ tó ṣẹ ní December 2015 lórí àwọn aṣòfin rúfin ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. [10]

TheCable (April 2014 – January 2017)

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Soyombo bẹ̀rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi iṣẹ́ akọ́kọ́ The Cable's first editor ní April 2014. Ní àksìkò yíì, ó fi ìri rẹ̀ pamọ́ gẹ́gẹ́ bíi akólẹ̀ láti tú àṣírí àwọ ní Nigerian Customs Service.[11]

Nígbà tí yóò fi di òpin 2017, ó fi ipò sílẹ̀ ó sì bẹ̀rẹ̀ òkòwò. Síbẹ̀síbẹ̀ ó ṣì tẹ̀síwájú láti kọ ìròhìn ní TheCable website.[12]

Ó ṣe àkànṣe iṣẹ́ ìwádìí tí àkọ́lé rẹ̀ jẹ́ owó ẹ̀yìn N46,000 "mo wa ọkọ̀ tí a jígbé láti Abuja lọ sí Èkó, mo tí padà dé!" Tí a tẹ̀ jáde ní May 2018 sí ìkànnì ìwé ìròyìn .[13] Soyombo fi ìwádìí rẹ̀ lélẹ̀ pé fún odindi ọjọ́ méjì, òun wa ọkọ̀ tí a jígbé láti Abuja lọ sí Èkó láì kósí ọwọ́ àwọn agbòfinró pẹ̀lú bí ó ṣe gbà ọ̀dọ̀ àwọn ọlọ́pàá kọjá. [14]

Ní 2019, ó ṣe àkànṣe iṣẹ́ ìwádìí lórí èrú nínú ìjọba orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, pàápàá àwọn ọlọ́pàá àti ọgbà ẹ̀wọ̀n.[15][16] Soyombo lọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọjọ́ ní Pedro Police Station, Shomolu, Èkó, ní abẹ́ orúkọ "Ojo Olajumoke".[17]Ó sì tún lò ọjọ́ mẹ́jọ ní ọgbà ẹ̀wọ̀n ìkòyí .[18]

Lẹ́yìn náà ni The Guardian fi yéwa pé àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ń gbìyànjú àti fi kélé òfin gbé Soyombo, èyì tí ó ṣokùn fa bí ó ṣe fara pamo fún ìgbà díẹ.[19] Láti ìgbà yìí ni The Nigerian Correctional Service (NCS) kò ti gbìyànjú àti fi kélé òfin gbée mọ́ .[20]

Èyí tí ó ṣokùnfa ìpèdè yìí lórí ẹ̀rọ ayélujára Twitter hashtag #KeepFisayoSafe ní èyí tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn oníròyìn àti àwọn ọmọ Nàìjíríà ń pè fún àbò rẹ̀ .[21][22][23]

Soyombo di ipò kékeré kán mú ní International Centre for Investigative Reporting (ICIR). Ó ṣe ìwádìí lórí àkórī "Ẹ̀gbin, òórùn àti ìkówó ìlú jẹ ní áwọn ilé ìgbókùú sì àti ìtẹ́ òkú ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà".[24]

Sahara Reporters (2018–2019)

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní May 2018, wọ́n kéde Soyombo gẹ́gẹ́ bí ọ̀gá àgbà ilé iṣé oníròyìn lórí ẹ̀rọ ayélujára, Sahara Reporters. Ó fi ipò rẹ̀ sílẹ̀ lẹ́yìn ọdún kan tí ó sì gbájùmọ́ ìwádìí rẹ̀ kíkún ní ṣíṣe.[25]

Foundation for Investigative Journalism (FIJ) (2020–present)

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní 2020, Soyombo dá the not-for-profit investigative journalism organisation FIJ sílẹ̀.[26][27]

Ní July 2019, lẹ́yìn oṣù kan tí ó ti fi SaharaReporters sílẹ̀, Soyombo lọ gẹ́gẹ́ bi aṣè ìwádìí, tí ó sì lo ọ̀sẹ̀ méjì àti ọjọ́ márùún ní àgọ́ ọlọ́pàá pẹ̀lú ọjọ́ mẹ́jọ ní ọgbà ẹ̀wọ̀n ìkòyí nítorí àti gbá àwọn oníwà ìbàjẹ́ mú ṣínkún. Láti ní ìrírí ọ̀nà tí wọ́n gbà ṣiṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ náà, Soyombo — tí ó mú ìlànà Ojo Olajumoke —parọ́ ẹ̀ṣẹ̀ ní èyí tí ó mú kí àwọn ọlọ́pàá fi kélé òfin gbée èyí tí ó mú kí ó sì dì èrò ọgbà ẹ̀wọ̀n.[28]

Nígbà tí a tẹ ìwé náà jáde ní october, àwọn.ìjọba fi kélé òfin gbée títí tí àwọn ará Twitter fi ṣe ìwọ́de #KeepFisayoSafe èyí tí ó fà ọwọ́ wọn padà.[29]

Ní oṣù tó tẹ̀lé, Soyombo tún ṣe ìwádìí, ní àkókò yìí ó lọ ọjọ́ mẹ́wàá gẹ́gẹ́ bí aláìsàn ní Federal Neuropsychiatric Hospital, Yaba, Èkó, tí a mọ̀ sí Yaba Left'.[30]

Ní January àti February 2021, ọ tẹ ìwé 'Portraits of Blood"', ó ṣe ìwé yìí láti fi sọri ìfarapa àwọn olù fẹ̀hónú hàn tí wọn fara kásá ọta ìbọn lọ́wọ́ àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò. Níbẹ̀ ní a sì tí rí awọn ẹ̀ṣọ́ ọmọ ológun tí wọ́n farapa nígbà tí àwọn àti Boko Haram jọ wọ̀yáàjà sùgbọ́n tí kò sí ìtọjú tó péye fún wọn.

l
ẹ̀ṣọ́ ológun tí T gé ẹsẹ̀ rẹ̀ lẹ́yìn tí àwọn Boko Haram yìbọn fún un lẹ́sẹ̀, ó sì bẹ̀bẹ̀ fún ìsinmi ọlọ́ṣù mẹ́rìnlélógójì (44) èyí tí wọn padà fún. Síwájú síi àti ní àkótán àwọn ọmọ ogun tí wọ́n pàdánù ìgbọ́rán ni won gba ìtọ́jú tó péye tí wọ́n sì yànda wọn. rí ìwà yìí gẹ́gẹ́ bí ìwà rere. Ó rí ìwà yìí gẹ́gẹ́ bíi èyí tí ó dára jù láti ìgbà tí ó ti ń ṣe iṣẹ́ aṣèwádìí s

i i s i i i i i i i

3 Bribery, bail for sale... Lagos police station where innocent civilians are held and criminals are recycled October 14, 2019 TheCable
4 Bed-space corruption, terrible food, well-fed rats... Many things not right at 'Yaba Left' June 22, 2020 TheCable
5 PORTRAITS OF BLOOD (II): Names, photos, videos – how Lekki #EndSARS protesters were shot January 26, 2021 TheCable
6 ARROWS OF GOD: One of Nigeria's Biggest Orphanages Is Trading Babies for Cash August 10, 2023 FIJ [6]

Ní Thursday, June 18, 2020, Soyombo kọ ìròhìn ránpẹ́ lórí ẹ̀rọ ayélujáraTwitter account rẹ̀ @fisayosoyombo wípé Gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ tí ó jẹ kọjá , Abiola Ajimobi, fila ṣasọ bora.[31] Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn mọ̀lẹ́bí rẹ̀ wípé èyí kò rí bẹ́ẹ̀ Soyombo kọ̀ láti ṣe ayípadà ohun tí ó kọ, dípò èyí ó wípé ibi tí òun tí mú ìròyìn náà wá jẹ́ òótó wípé Gómìnà ti papò dà.

Ní ọdún ril 2019 ó ṣe átẹ̀jáde ìwé. Soyombo gbìyànjú láti ṣiṣẹ́ takuntakun nípa ìwádìí àti ìròhìn nípa ṣíṣe ìwọ́de tí ó rú àwọn ènìyàn ìgbìmọ̀ láwùjọ the truth .[32][33]

Year Award Category Result Story
2021 One World Media Awards International Journalist of the Year Finalist Portraits of Blood
Karpoor Chandra Kulish International Award for Excellence in Journalism Main Honourable Mention Undercover Investigation on Nigeria's Criminal Justice System
2020 Fetisov Journalism Award Outstanding Investigation Second Prize Undercover Investigation on Nigeria's Criminal Justice System
Kurt Schork Awards in International Journalism Local Reporter Winner Undercover Investigation on Nigeria's Criminal Justice System
West Africa Media Excellence Award Investigative Reporting Winner Undercover Investigation on Nigeria's Criminal Justice System
WJP Anthony Lewis Prize for Exceptional Rule of Law Journalism Prize for Journalism Honourable Mention Undercover Investigation on Nigeria's Criminal Justice System
One World Media Awards International Journalist of the Year Finalist Undercover Investigation on Nigeria's Criminal Justice System
People Journalism Prize for Africa Main Award Winner Undercover Investigation on Nigeria's Criminal Justice System
2019 Diamond Award for Media Excellence (DAME) Investigative Reporter of the Year Winner REPORTER'S DIARY: With N46,000 bribe, I drove a 'stolen' car from Abuja to Lagos, and back!
2017 Wole Soyinka Award for Investigative Reporting Online Winner UNDERCOVER: In Borno, children are dying at IDP camps, foodstuffs are 'disappearing' at SEMA store
2016 African Media Initiative awards Maritime Economy Winner Undercover Investigation: Nigeria's Customs of Corruption, Bribery and Forgery
Wole Soyinka Award for Investigative Reporting Online Second Runner-Up Undercover Investigation: Nigeria's Customs of Corruption, Bribery and Forgery
Wole Soyinka Award for Investigative Reporting Online Winner Forgotten Soldiers
Wole Soyinka Award for Investigative Reporting (The Nigerian Investigative Journalist of the Year) Winner Forgotten Soldiers
Diamond Award for Media Excellence (DAME) Investigative Reporter of the Year 2nd Runner-up Undercover Investigation: Nigeria's Customs of Corruption, Bribery and Forgery
Free Press Awards Hans Verploeg Newcomer of the Year Winner Forgotten Soldiers
PricewaterhouseCoopers (PwC) Journalism Excellence Awards Journalist of the Year (Business and Economy Reporting) Winner Undercover Investigation: Nigeria's Customs of Corruption, Bribery and Forgery

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. Aworinde, Tobi (January 17, 2021). "My online paper will focus on investigative works and reporting social injustices —Multiple award-winning journalist, Soyombo". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  2. The, Cable (January 18, 2021). "INTERVIEW: I left editorship for investigative reporting with the recklessness and innocence of a child playing with sand, says Soyombo". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  3. "UNDERCOVER INVESTIGATION (I): Bribery, bail for sale... Lagos police station where innocent civilians are held and criminals are recycled". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-10-14. Retrieved 2021-08-02.
  4. "UNDERCOVER INVESTIGATION (II): Drug abuse, sodomy, bribery, pimping... The cash-and-carry operations of Ikoyi Prisons". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-10-21. Retrieved 2021-08-02.
  5. "'Keep Soyombo safe' -- Nigerians seek protection for journalist who exposed rot in prisons". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-10-22. Retrieved 2021-08-02.
  6. "REPORTER'S DIARY: With N46,000 Bribe, I drove a 'stolen' car from Abuja to Lagos, and back!". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2018-05-31. Retrieved 2021-08-02.
  7. "fisayo, Author at Ventures Africa". Ventures Africa (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  8. "At 50, the Jahman Anikulapo I Know By 'Fisayo Soyombo". Sahara Reporters. 2013-01-16. Retrieved 2021-08-02.
  9. Olaleye, Olawale (October 27, 2019). "The Fisayo Soyombo Challenge". THISDAYLIVE (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  10. "UNDERCOVER INVESTIGATION: Nigeria's 'Customs of corruption, bribery and forgery'". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2015-12-31. Retrieved 2021-08-02.
  11. "UNDERCOVER INVESTIGATION: Nigeria's 'Customs of corruption, bribery and forgery'". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). December 31, 2015. Retrieved May 16, 2021.
  12. Akinola, Sikiru (October 23, 2019). "Soyombo: Journalists as endangered species". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  13. Aikulola, Sunday (January 19, 2021). "'With Foundation for Investigative Journalism, we want to break new grounds'". The Guardian Nigeria News – Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  14. Kolawole, Simon (June 14, 2020). "Enter the Daredevil Journalist". THISDAYLIVE (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  15. Egbunike, Nwachukwu (October 23, 2019). "Nigerian journalist under threat of arrest for exposé of police and prison corruption". Global Voices Advox (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  16. The Interview, Editors (November 12, 2019). "Why I revealed My Identity In The Prisons Story – Fisayo Soyombo". TheInterview Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  17. Omilana, Timileyin (October 23, 2019). "Prison authorities to investigate Fisayo Soyombo's Ikoyi prison allegations". The Guardian Nigeria News – Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  18. Ufuoma, Vincent (October 22, 2019). "Nigerians urge protection of journalist over undercover work" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  19. Bakare, Tonye (October 22, 2019). "Nigerian authorities plan to arrest Fisayo Soyombo over undercover investigations". The Guardian Nigeria News – Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  20. "We've No Intention Of Arresting Investigative Journalist, Fisayo Soyombo -Prisons Boss". Sahara Reporters. October 22, 2019. Retrieved May 16, 2021.
  21. "Fisayo Soyombo life dey at risk?". BBC News Pidgin. https://www.bbc.com/pidgin/tori-50142572.
  22. O Royal, David (October 22, 2019). "Arrest threat: Nigerians seek protection of investigative journalist, Fisayo Soyombo". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  23. Famuyiwa, Damilare (October 22, 2019). "Nigerians seek Fisayo Soyombo's protection after undercover investigation in police cell". Pulse Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  24. Savingrace, Oluwabukunmi (May 10, 2021). "Fisayo Soyombo: Celebrating Black Excellence In Journalism". Duke International Magazine (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  25. Kojah, Senami (January 17, 2020). "Nigerian newsrooms are using these strategies to combat media repression". International Journalists' Network (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  26. Egwu, Patrick (May 12, 2020). "This journalist wants to raise the bar for investigative reporting in Nigeria". International Journalists' Network (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved May 16, 2021.
  27. Ishaku, Winnie (January 20, 2021). "FIJ: New Media Platform Breaks Into Industry With #EndSARS Investigative Series". HumAngle (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on May 16, 2021. Retrieved May 16, 2021.
  28. "UNDERCOVER INVESTIGATION (II): Drug abuse, sodomy, bribery, pimping... The cash-and-carry operations of Ikoyi Prisons". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-10-21. Retrieved 2021-08-02.
  29. "Prison authorities to investigate Fisayo Soyombo's Ikoyi prison allegations". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-10-23. Retrieved 2021-08-02.
  30. "UNDERCOVER INVESTIGATION (I): Bed-space corruption, terrible food, well-fed rats... Many things not right at 'Yaba Left'". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-01-22. Retrieved 2021-08-02.
  31. "Fact check by Fisayo Soyombo reveals Ajimobi is 'dead' but still on life support (PHOTO)". LiveTimes9ja (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-06-19. Retrieved 2021-08-02.
  32. "'Fisayo Soyombo selected for Reuters Institute fellowship at Oxford University". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2022-04-28. Retrieved 2022-10-26.
  33. "Nigerian investigative journalist, Soyombo, wins prestigious Oxford fellowship". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2022-04-28. Retrieved 2022-10-26.