Ganiyu Dawodu
Ganiyu Olawale Dawodu /θj/ (1935–2006) ti gbogboayé mọsì G.O.D. ní ìlú Èkó, jẹ ọmọorílè-èdè Nàìjíríà olóṣèlú àti ajafun ètò ọmọ ènìyàn lórí ọ̀rọ̀ ètò ìṣèlú àwa ará wá tí a mọ sì ìjọba alagbada. O jẹ ọkan gbogì láàárín àwọn ọmọ ẹgbẹ òṣèlú ti ẹgbẹ National Democratic Coalition ti o gbà ju gbaja sìwọ n pè ní NADECO ni orílè-èdè Nàìjíríà lákòókò ìṣe ìjọba oga àgbà ológun ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà ọ̀gágun Sani Abacha. Akojopo àwọn ẹgbẹ òṣèlú náà i wọn jà fita fita láti rí wípé wọn dá gbá jù gbá jà olóṣèlú àti olórò ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà ní wọ mo sì M.K.O Abiola kalẹ ni ahamo ọgbà ẹ̀wọ̀n, nínú igbiyanju won, wọn tí ohùn náà mọ àtìmọ́lé àwọn ìjọba látàrí akitiyan rẹ láti gbà òmìnira fún Abiola.[1] Ni ọdun 2000, o ni ìdojúkọ pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ òṣèlú re látàrí wípé tani yíò jẹ́ oga adarí àgbá ẹgbẹ òṣèlú náà fún ẹka ti ẹgbẹ Alliance for Democracy ní ìpínlè ẹ̀kọ́. O se àtakò sì jíjẹ gómìnà ìpínlè ẹ̀kọ́ ní gbá náà Bola Tinubu ní ọdún 1998-1999 o sì ṣe àti leyin fún olóògbé Funsho Williams, ẹniti òjé olórí alátakò sì Tinubu ní gbá náà. Àríyànjiyàn yí tún tẹ síwájú dì ọdún 2000, nígbà tí o fí dì ọdún 2003, o fí ẹgbẹ òṣèlú náà sílè láti lọ darapọ mọ ẹgbẹ òṣèlú mí látàrí rògbòdìyànto bẹ sílè laarin wọn lpsi ẹgbẹ òṣèlú Progressives Action Coalition ni bí tí o tí dì jẹ gẹgẹbi ọmọ ẹgbẹ tí ẹgbẹ òṣèlú náà fa kalẹ láti díje dùn ipò gómìnà ìpínlè ẹ̀kọ́ lábé asiya ẹgbẹ náà.[2] Dawodu bí sì ìlú Ẹkọ ó lọ si ilé ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ ti Ansar Ud Deen, Okepopo, ni ìlú Èkó. leyin náà o tẹsiwaju láti tún kò ẹ̀kọ́ ni ilé ẹ̀kọ́ Ahmadiya High School síwájú kí o tó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ gíga St Gregory's College, Lagos. Lákòókò ìṣe ìjọba Olómìnira àkọ́kọ́ ní orílè-èdè Nàìjíríà, o jẹ ọkan lára àwọn aṣojú àgbègbè ni ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìbílè ẹ̀kọ́ leyin ìgbà náà lọ tún dùn ipò alaga ìbílè tí o sì wọlé.