Gbénga Adébóyè (Fúnwọtán/Jengbetíèlè)
| Gbenga Adeboye | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | 30 Oṣù Kẹ̀sán 1959 Odeomu, Western Region, British Nigeria (now in Osun State, Nigeria) |
| Orúkọ míràn | Funwontan |
| Iṣẹ́ | Comedian |
| Olólùfẹ́ | Omolara Gbenga Adeboye[1] |
| Àwọn olùbátan | Damilola Gbenga Adeboye (Daughter)[2] |
Gbénga Adébóyè a bi ní Ọgbọ̀njọ́ Oṣù Kẹsàn ọdún 1959 ó sì jáde láyé ní Ọgbọ̀njọ́ Oṣù Kẹrin ọdún 2003 jẹ́ akọrin, apanilẹ́rìn-ín, òǹsọ̀rọ̀ lórí rédíò, olùgbékalẹ̀ ìròyìn àti olùdarí ayẹyẹ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, tí ìnagijẹ rẹ̀ ń jẹ́ Fúnwọntàn tàbí Jengbetíèlè . Títí di ìgbà ikú rẹ̀, ó gbajúmọ̀ kárí ayé nínú iṣẹ́ eré ìnàjú. [3]
Ìgbésí ayé rẹ̀ ní kékeré
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]A bí Elijah Olúwágbémiga Adébóyè ní ọgbọ̀njọ́ oṣù kẹsàn-án ọdún 1959 ní Ọdẹ-Òmu, Ìpínlẹ̀ Osun, ní gúúsù ìwọ̀ oòrùn Nàìjíríà, tíí ṣé apá Ìwọ̀ Oòrùn Áfíríkà .
Iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Adébóye jẹ́ olùdari ètò rédíò olókìkí kan tí a gbé kalẹ̀ ní ilé iṣẹ́ rédíò ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ní ìbẹ̀rẹ̀ ọdún 1980 níbi tí wọ́n ti fun ní ìnagijẹ Fúnwọntán Olódù . Obìnrin òṣèrébìnrin ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kan, Idowu Philips, tí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ rẹ̀ àkọ́kọ́ jẹ́ ẹ̀bùn láti ọ̀dọ̀ Gbenga Adeboye, ṣàpèjúwe Gbénga Adébóyè gẹ́gẹ́ bí apanilẹ́rìn-ín onínúure. Àwọn olùfẹ́ rẹ̀ tún pè é ní oníṣòwò àti olùṣe eré ìtàn Odù kí ó tó jáde láyé látàrí àrùn tí ó ní í ṣe pẹ̀lú kíndìnrín ní ọgbọ̀njọ́ oṣù kẹrin ọdún 2003.
Wíwò síwájú síi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- Yinka Ayefele - ṣe ayẹyẹ kan fún Gbénga Adébóyè.
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "I Kill Ram Yearly For My Husbands Remembrance - ...Regret Ever Marrying From Adeboyes Family - Lar". modernghana.com. Retrieved 11 February 2015.
- ↑ "Dad was a car freak — Gbenga Adeboye's daughter". The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper. Archived from the original on 29 January 2015. Retrieved 11 February 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid
<ref>tag; no text was provided for refs named:0