Jump to content

Gbénga Adébóyè (Fúnwọtán/Jengbetíèlè)

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Gbenga Adeboye
Ọjọ́ìbí(1959-09-30)30 Oṣù Kẹ̀sán 1959
Odeomu, Western Region, British Nigeria (now in Osun State, Nigeria)
Orúkọ mírànFunwontan
Iṣẹ́Comedian
Olólùfẹ́Omolara Gbenga Adeboye[1]
Àwọn olùbátanDamilola Gbenga Adeboye (Daughter)[2]

Gbénga Adébóyè a bi ní Ọgbọ̀njọ́ Oṣù Kẹsàn ọdún 1959 ó sì jáde láyé ní Ọgbọ̀njọ́ Oṣù Kẹrin ọdún 2003 jẹ́ akọrin, apanilẹ́rìn-ín, òǹsọ̀rọ̀ lórí rédíò, olùgbékalẹ̀ ìròyìn àti olùdarí ayẹyẹ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, tí ìnagijẹ rẹ̀ ń jẹ́ Fúnwọntàn tàbí Jengbetíèlè . Títí di ìgbà ikú rẹ̀, ó gbajúmọ̀ kárí ayé nínú iṣẹ́ eré ìnàjú. [3]

Ìgbésí ayé rẹ̀ ní kékeré

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bí Elijah Olúwágbémiga Adébóyè ní ọgbọ̀njọ́ oṣù kẹsàn-án ọdún 1959 ní Ọdẹ-Òmu, Ìpínlẹ̀ Osun, ní gúúsù ìwọ̀ oòrùn Nàìjíríà, tíí ṣé apá Ìwọ̀ Oòrùn Áfíríkà .

Iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Adébóye jẹ́ olùdari ètò rédíò olókìkí kan tí a gbé kalẹ̀ ní ilé iṣẹ́ rédíò ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ní ìbẹ̀rẹ̀ ọdún 1980 níbi tí wọ́n ti fun ní ìnagijẹ Fúnwọntán Olódù . Obìnrin òṣèrébìnrin ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kan, Idowu Philips, tí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ rẹ̀ àkọ́kọ́ jẹ́ ẹ̀bùn láti ọ̀dọ̀ Gbenga Adeboye, ṣàpèjúwe Gbénga Adébóyè gẹ́gẹ́ bí apanilẹ́rìn-ín onínúure. Àwọn olùfẹ́ rẹ̀ tún pè é ní oníṣòwò àti olùṣe eré ìtàn Odù kí ó tó jáde láyé látàrí àrùn tí ó ní í ṣe pẹ̀lú kíndìnrín ní ọgbọ̀njọ́ oṣù kẹrin ọdún 2003.

Wíwò síwájú síi

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "I Kill Ram Yearly For My Husbands Remembrance - ...Regret Ever Marrying From Adeboyes Family - Lar". modernghana.com. Retrieved 11 February 2015.
  2. "Dad was a car freak — Gbenga Adeboye's daughter". The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper. Archived from the original on 29 January 2015. Retrieved 11 February 2015. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  3. Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid <ref> tag; no text was provided for refs named :0