Gifty Anti
| Gifty Anti | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | 23 Oṣù Kínní 1970 Tema, Ghana |
| Iléẹ̀kọ́ gíga | Mfantsiman Girls Secondary School Ghana Institute of Journalism |
| Iṣẹ́ | ọníròyìn |
| Gbajúmọ̀ fún | olùgbèjà ìbálòpọ̀ |
| Olólùfẹ́ | Nana Ansah Kwao IV |
Oheneyere Gifty Anti (tí ọjọ́ìbí rẹ̀ jẹ́ January 23, 1970) jẹ́ ọníròyìn àti olùgbọhùn sáféfé àrà ìlù Ghana. Òún ní olùgbàlejò ètò Standpoint, èyí tí ó ń jíròrò àwọn ọ̀ràn tí ó kan àwọn obìnrin lórí Ghana Television.[1][2][3][4][5][6]
Ìgbésí ayé rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Gifty jẹ́ ọmọ ìbílẹ̀ Cape Coast ṣùgbọ́n wọ́n bí sí àti wọ́n tún dàgbà sí Tema, ní Ghana.[7][8][9] Ó jẹ́ ọmọ ìkẹyìn nínú ìdílé ọmọ mẹ́jọ. Nítorí ìṣòro ọrọ̀ ajé, ó kọ́kọ́ ń ṣiṣẹ́ gbẹ́nàgbẹ́nà láti fí lé jẹ́ùn.[10]
Gifty jẹ́ ìyàwó sí Nana Ansah Kwao IV, Ọlùdarí ti Akwamu Adumasa.[11] Wọ́n ṣé Ìgbéyàwó wọn ní Trinity Baptist Church ní ọjọ́ 25 Oṣù Kéwáà, ọdún 2015.[12] Ó bí ọmọ àkọ́kọ́ rẹ̀ ní ọjọ́ kọkànlá oṣù kẹ́jọ̀ ọdún 2017.[13] [14]
Ó tí gba ọlá àti oyè tụntụn, éyí tí wọ́n fún un lẹ́yìn tí wọ́n fún un ní Fellowship of the Boardroom Institute (FBI) láti Accra Business School.
Ẹ̀kọ́ rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Gifty Anti kọ́ ẹ̀kọ́ praịmarị rẹ̀ ní ilé-ẹ̀kọ́ ìpìlẹ̀ Tema community 8 "Number 1" Basic School. Lẹ́yìn náà, ó lọ sí Mfantsiman Girls Secondary School níbi tí ó ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí olórí eré ìdárayá. Bákan náà, ó jẹ́ ọmọ ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti Ghana Institute of Journalism níbi tí ó ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí Kọmíṣọ́nà fún àwọn Obìnrin.[10][15][16] Ó tún ní oyè Master nínú iṣẹ́ ìròyìn àgbáyé láti City, University of London.
Ìṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Gifty bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ lórí tẹlifíṣọ̀n gẹ́gẹ́ bí akẹ́kọ̀ọ́ ní Ghana News Agency, lẹ́yìn náà ó lọ sí Ghanaian Times gẹ́gẹ́ bí akẹ́kọ̀ọ́. Lẹ́yìn náà, ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí akẹ́kọ̀ọ́ ní Ghana Broadcasting Corporation (GBC), níbi tí wọ́n tún fún un ní àǹfààní láti ṣe iṣẹ́ orílẹ̀-èdè rẹ̀.[17]
Lẹ́yìn náà, ó di olùgbékalẹ̀ tẹlifíṣọ̀n, olùkọ́ àti olùgbèjà ìbálòpọ̀.[15] Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, òun ni Olórí Àgbà fún GDA Concept àti olùgbàlejò fún Stand Point , ìfọ̀rọ̀wérọ̀ lórí àwọn ọ̀ràn obìnrin.[18][19]
Ní ọdún 2019, ó ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìwé rẹ̀ tí àkọlé rẹ̀ jẹ́ A Bit Of Me ; ìwé náà dé ipò àkọ́kọ́ lórí Amazon lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan tí wọ́n ti tẹ̀ ẹ́ jáde. [20]
Òun lọ jẹ́ olùdásílẹ̀ àti ààrẹ Girl in Need Foundation àti Awo Dansoa Reading Project. Ó tún jẹ́ aṣójú fún ìpolongo lòdì sí ikú àwọn ọmọ tuntun.[21]
Àwọn oyè tí ọ gbà
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- Tell It Moms Exemplary Resilience Feminist Honour 2019 Archived 2025-01-21 at the Wayback Machine.
- National Malaria Advocate[22]
- Most Inspiring Woman In Media[23]
- Most influential women[24]
- United Nation’s MDGs 4&5 Ambassador Award 2012[9]
- The African Women in Leadership Organisation’s Excellence Award[9]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Oheneyere Gifty Anti looks younger than ever at age 50" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì).
- ↑ Kunateh, Masahudu Ankiilu (8 July 2013). "Gifty Anti Deepens Support For Girl-Child Education –As She Launches Girl In Need Foundation". thechronicle.com. Retrieved 9 July 2015.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
- ↑ "Archived copy". Archived from the original on 26 May 2021. Retrieved 13 April 2019. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Glitz top 100 inspirational women – Page 100 – Glitz Africa Magazine" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-05-28.
- ↑ "The StandPoint Profile". thestandpoint.com. Archived from the original on 10 July 2015. Retrieved 9 July 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "GIJ Women's Commission to honour Oheneyere Gifty Anti tonight". www.ghanaweb.com. Retrieved 2019-05-18.
- ↑ Mireri, Julian (2020-10-26). "Dr Gifty Anti biography: Husband, siblings, wedding, daughter, photos". Yen.com.gh - Ghana news. (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2024-05-12.
- ↑ Asubonteng, Ama Serwaa. "GIFTY ANTI MAKES A "STANDPOINT" FOR WOMEN IN GHANA". The Herald. Archived from the original on 18 October 2015. Retrieved 1 August 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - 1 2 3 "Dr Gifty Anti biography: Husband, siblings, wedding, daughter, photos". 26 October 2020.
- 1 2 Myjoyonline.com. "Ghana News - Joy FM's Personality Profile: Gifty Anti talks work, women, romance and rumours". www.myjoyonline.com. Archived from the original on 2015-10-22. Retrieved 2015-08-01. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "I'm dyslexic – Nana Ansah Kwao". www.ghanaweb.com (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2019-03-16.
- ↑ "Oheneyere Gifty Anti & Husband In Church (PHOTOS). | ANAPUAFM.COM - Today's Hits Yesterday's Classics!" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2015-10-26. Retrieved 2021-10-12.
- ↑ "Gifty Anti And Husband Outdoor 'Royal Baby'". Archived from the original on 2023-03-26. https://web.archive.org/web/20230326162747/https://www.peacefmonline.com/pages/showbiz/news/201708/324835.php. Retrieved 2018-06-19.
- ↑ Empty citation (help)
- 1 2 "I have been a carpenter before, Gifty Anti reveals". myjoyonline.com. 11 March 2011. Retrieved 9 July 2015.
- ↑ "Int'l Women's Day: The Gifty Anti factor - How her 'feminist' father influenced her life - MyJoyOnline.com". www.myjoyonline.com (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 8 March 2021. Retrieved 2021-08-29.
- ↑ "I never envisioned myself as a broadcaster -Gifty Anti". Graphic Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-08-29.
- ↑ "Photos: Gifty Anti, Nana Ansah Kwao IV celebrate 3 years of marriage". www.myjoyonline.com. Archived from the original on 2018-10-16. Retrieved 2019-05-19.
- ↑ "Gifty Anti shares inspiring story of how she made it in her career". www.ghanaweb.com. Retrieved 2019-06-17.
- ↑ Empty citation (help)
- ↑ "Gifty Anti's 'A Bit of Me' number 1 on Amazon in less than a week". www.myjoyonline.com. Archived from the original on 2020-01-27. Retrieved 2020-01-27. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "NMCP appoints Gifty Anti as National Malaria Advocate - MyJoyOnline.com". www.myjoyonline.com (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 29 April 2021. Retrieved 2021-08-29.
- ↑ "Ghana's Most Inspiring Women Awards: Gifty Anti, others win big at maiden event". Prime News Ghana (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-09-18. Retrieved 2021-08-29.
- ↑ "Shatta Wale, Gifty Anti, Others Win Big At Ghana Actors And Entertainers Awards [Full List]". Modern Ghana (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-08-29.
- CS1 Èdè Gẹ̀ẹ́sì-language sources (en)
- All articles with dead external links
- Articles with dead external links from March 2022
- Articles with invalid date parameter in template
- Articles with permanently dead external links
- Pages with citations using unsupported parameters
- Pages with empty citations
- Webarchive template wayback links