Glory Emmanuel Edet
| Glory Emmanuel Edet | |
|---|---|
| Orílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Ẹ̀kọ́ | Department of Agricultural Economics and Extension |
| Iléẹ̀kọ́ gíga | University of Uyo |
| Title | Commissioner Ministry od Women Affairs |
Glory Emmanuel Edet
listen ni Nigerian àrẹbìnrin àti ajà-fẹ́tọ̀ọ́ ọmọbìnrin àti ọmọdé. Ó jẹ́ Kọmíṣọ́nà onígbà méjì fún àwọn olobìnrin àti ìṣàkóso-àbò ní ìpínlẹ̀ Akwa Ibom.[1] A kọ́kọ́ yàn án ní ọdún 2013, a tún yàn án sí ipò kan náà ní ọdún 2015 láti ọwọ́ Udom Gabriel Emmanuel. Ní ọdún 2015, ó bẹ̀rẹ̀ ètò ìfagbárafún-ni fún àwọn opó ní èyí tí a sì yan ènìyàn kọ̀ọ̀kan ní gbogbo agbègbè gẹ́gẹ́ bí
Ó jẹ́ alágbèéká ńlá fún àwọn Obìnrin tí ó sì ṣiṣẹ́ tọkàntọkàn lórí ìpènijà takọ-tabo, àwọn tí ò ní àǹfààní àti àwọn tí ò jìnà sí ewu ní àwùjọ. Ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí Olùkọ́ni ni ẹ̀ka ẹ̀kọ́ oníṣẹ́ àgbẹ̀, olùṣírò-owó-àwùjọ àti èyí tó dàbí rẹ̀, Fáṣítì Uyo, èyí tí ó jẹ́ àkọ́kọ́ fún un nígbà tí a yàn án láti ọwọ́ ìjọba ìpínlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí i Kọmíṣọ́nà. Dr Glory Edet jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ onírúurú ẹ̀ka akọ́ṣẹ́mọṣẹ́.[2]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "We have transformed prostitutes into entrepreneurs". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2016-06-11. Retrieved 2022-02-23.
- ↑ "Dr Glory Edet - Akwa Ibom State Government" (in en-US). Akwa Ibom State Government. Archived from the original on 2019-07-02. https://web.archive.org/web/20190702020621/https://akwaibomstate.gov.ng/dr-glory-edet/.