Habibah Ruth Garba
| Habibah Ruth Garba | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | Orilẹ-ede Nàìjíríà |
| Ọmọ orílẹ̀-èdè | Orilẹ-ede Nàìjíríà |
| Iṣẹ́ | Ọmọ ìlẹ̀ṣẹ̀ ológun ojú òfurufú |
| Gbajúmọ̀ fún | Àkọ́kọ́ obìnrin tí o di ipò Air Commodore ni ile-iṣẹ ọmọ ológun ojú òfurufú orílè-èdè Nàìjíríà |
| Awards |
|
Habibah Ruth Garba jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ ogun ojú ọ̀run ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà . Òun ni obìnrin àkọ́kọ́ tí wọ́n gbéga sí ipò Air Commodore nínú ẹgbẹ́ ọmọ ogun ojú ọ̀run ní Nàìjíríà. Ó wọ àmì ẹ̀yẹ Karis ní ọdún 2013 àti Female Achievers' Award of the Women in Management, Business and Public Service (WIMBIZ) 2018 ní Nàìjíríà .
Iṣẹ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Habibah Ruth Garba jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ ológun ojú ọ̀run ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Òun ni obìnrin àkọ́kọ́ tí wọ́n gbéga sí ipò Air Commodore nínú ẹgbẹ́ ọmọ ológun ojú ọ̀run ní orílè-èdè Nàìjíríà. Ó gba àmì-ẹ̀yẹ Karis ti ọdún 2013. Èyí jẹ́ ẹ̀bùn ọdọọdún ti Ilé Ìjọ Household of God ní Nàìjíríà. Ẹ̀bùn náà jẹ́ ara ètò ayẹyẹ ọdọọdún ti GRACE ti ìjọ tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ ní ọdún 1990.[1][2][3] Ó tún wọ àmì-ẹ̀yẹ Female Achievers' Award nínú ìpàdé Women in Management, Business and Public Service (WIMBIZ) ti ọdún 2018. A ṣe àpérò náà láti ṣe àwọn ètò tí ó ń fúnni níṣìírí, fúnni ní agbára àti láti gbé ìṣojú àwọn obìnrin lárugẹ ní àwọn ẹ̀ka ìjọba àti ti aladani.[4]
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Adadevoh's Karis: Worthy honour for an amazon". December 11, 2015.
- ↑ Simon Echewofun Sunday (6 December 2013). "Nigeria: First Female Air Force General Wins 2013 Karis Award". Daily Trust – via allafrica.com.
- ↑ "Bling Pastor: Chris Okotie shows off at Karis awards". P.M. News. December 10, 2013.
- ↑ "Highlights of the WIMBIZ Annual Conference 2018". 21 November 2018.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]