Hadiza Balarabe
Hadiza Balarabe | |
|---|---|
Balarabe in January 2025 | |
| Deputy Governor of Kaduna State | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
| Ó gun orí àga 29 May 2019 | |
| Gómìnà |
|
| Asíwájú | Barnabas Bala |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | Hadiza Sabuwa Balarabe 26 Oṣù Kẹjọ 1966[1] Sanga, Northern Region (now in Kaduna State), Nigeria |
| Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressive Congress |
| Alma mater | University of Maiduguri |
| Occupation |
|
Hadiza Sabuwa Balarabe (ọjọ́ ìbí 26 August 1966) tí a bí sínú ìdílé Alhaji Abubakar Mohammed [2] jẹ́ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà àti oníṣègùn òyìnbó to ti sise gẹ́gẹ́ bi igbá-kejì gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna láti ọdún 2019. [3] O jẹ igbá-kejì gómìnà obìnrin akọkọ ti Ìpínlẹ̀ náà, a sì yàn án sípò igbákejì gómìnà lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress ní ìdìbò gómìnà Nàìjíríà ti ó wáyé ní oṣù kẹta ọdún 2019, a sì tún yàn án sípò kan náà ní ìdìbò odun 2023. [4] [5]
Igbesiaye
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]A bi Balarabe ninu ìdílé Alhaji Abubakar Balarabe ni ìjọba ìbílè Sanga ni ìpínlè Kaduna . O lọ si Girls College Soba fun eto ẹkọ gírámà rẹ o si gba Iwe-ẹri Gbogbogboo ti Ẹkọ (GCE) ni ọdun 1982, Lẹhinna o gba wọle si Ile-ẹkọ giga olokiki ti Maiduguri lati kàwé nípa oògùn o pari pẹlu gbà iwe-ẹri MBBS ni ọdun 1986. [6]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Deputy Governor's Office – KDSG". Kaduna State Government. Archived from the original on 1 March 2024. Retrieved 19 January 2024.
- ↑ "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2025-02-14. Retrieved 2025-03-30.
- ↑ https://www.bbc.com/pidgin/articles/c519336n1wdo
- ↑ https://thenationonlineng.net/el-rufai-pays-may-salaries-ahead-of-sallah-celebration/amp/
- ↑ https://www.blueprint.ng/2019-which-way-southern-kaduna
- ↑ Empty citation (help)