Haliru Akilu
Haliru Akilu | |
|---|---|
| Director of National Intelligence Agency | |
| In office 1990–1993 | |
| Asíwájú | Albert Horsfall |
| Arọ́pò | Zakari Ibrahim |
| Chief of Defence Intelligence | |
| In office January 1990 – September 1990 | |
| Asíwájú | Babatunde Elegbede |
| Arọ́pò | Group Capt. I. Musa |
| In office August 1985 – July 1986 | |
| Asíwájú | Aliyu Gusau |
| Arọ́pò | Babatunde Elegbede |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | 2 Oṣù Kọkànlá 1947 Madobi, Northern Region, British Nigeria (now Madobi, Nigeria) |
| Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Alma mater | Nigerian Defence Academy |
| Military service | |
| Allegiance | |
| Branch/service | |
| Years of service | 1967–1993 |
| Rank | |
| Battles/wars | Nigerian Civil War |
Haliru Akilu (tí wọ́n bí ní ọjọ́ kejì Oṣù kọkànlá ọdún 1947) jẹ́ Ọ̀gá ológun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní ọdún 1990. [1]
Ìbẹrẹ Ìgbésí aye
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ilu Kano ni wọ́n bí Akilu sí, tí ó sì kọ́ ẹ̀kọ́ níbẹ̀.
Iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Ológun
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ní ọdún 1967 ni Akilu gbàṣẹ ologun lẹ́yìn ti ó lọ sí ilé-ẹ̀kọ́ Nigerian Defence Academy. Nígba tí ó sì di ọdún 1969, ó kópa nínú ìjà Ogun Abele Naijiria gẹ́gẹ́ bí adarí ọmọ ogun, ó sì farapa. Lẹ́yìn náà ló wá di Ọ̀gágun lẹ́ka ti 146 Infantry Battalion tó fòpin sí ìjà ẹ̀sìn Maitatsine tí ó wáyé ní ìlú Kano . [2]
Ẹkọ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Lẹ́hìn náà, ó lọ sí ilé-ìwé gíga Junior Staff College, Warminister (1973), Pakistan Command and staff College (1979), King's College London (1983), àti National Institute for Policy and Strategic Studies ní Kuru (1989).
Oye ologun
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Akilu darapọ̀ mọ́ Directorate of Military Intelligence. Gẹ́gẹ́ bí ọ̀gágun , ó kópa nínú ìpìlẹ̀ ìṣèjọba ológun ní ọdún 1983 tí ó lé Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Kejì kúrò tí wọ́n sì fi sípò agbára Major-General Muhammadu Buhari . [3] Ó rọ́pò General Aliyu Gusau gẹ́gẹ́ bí Olùdarí Ìmọ̀ye-ogun; ó sì kó ipa pàtàkì nínú ìdìjọba ológun lọ́dún 1985 tí wọ́n fi gba ìjọba Muhammadu Buhari sílẹ̀. [4] Lẹ́yìn ifipagbàjọba náà, Ọ̀gágun Babangida ( Olóye Oṣiṣẹ́ Ogun nígbà náà) lo ìsúnmọ́ rẹ̀ pẹ̀lú Akilu àti àwọn akẹ́kọ̀ọ́ mìíràn tí wọ́n kẹ́kọ̀ọ́ jáde ní NDA's Regular Course 3 (Babangida jẹ́ olùkọ́ NDA ní ìbẹ̀rẹ̀ ọdún 70s). [5]
Akilu ni a gbe ni DMI gẹgẹbi ìṣàkóso idakeji sí Ambassador Mohammed Lawal Rafindadi, Olubaṣepọ ọgagun Muhammadu Buhari ni ètò ààbò orílẹ-èdè. [6] [7] Ipò Akilu nínú Oludari Imọye Ologun ṣiṣẹ gẹgẹbi oye si Ajọ Aabo Orilẹ-ede . Akilu ko ipa pàtàkì ninu ètò iṣọkan gẹgẹ bi (Director of Military Intelligence) ninu ifipajoba ologun lọdun 1985 to fi le oga ologun ti ipinle naa General Muhammadu Buhari ti o si mu General Ibrahim Babangida a si ijoba. [8] Akilu ati Babangida ni ibatan timọtimọ torí pe iyawo Akilu ati Maryam Babangida jẹ ẹbi. [9] [10]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ https://blerf.org/index.php/biography/akilu-brigadier-haliru-rtd/
- ↑ https://web.archive.org/web/20160911231425/http://www.notablenigerians.com/?p=1162
- ↑ Siollun, Max. Siollun, Max. Soldiers of Fortune. Nigerian Politics from Buhari to Babangida 1983-1993.https://en.wikipedia.org/wiki/Haliru_Akilu#cite_ref-Siollun-SOFp8_3-0
- ↑ "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2025-02-23. Retrieved 2025-09-19.
- ↑ https://blerf.org/index.php/biography/akilu-brigadier-haliru-rtd/
- ↑ https://web.archive.org/web/20210608090914/http://www.waado.org/nigerdelta/nigeria_facts/militaryrule/omoigui/PalaceCoup-1985.htm
- ↑ Balogun, M.J.. The Route to Power in Nigeria: A Dynamic Engagement Option for Current and Aspiring Leaders.https://en.wikipedia.org/wiki/Haliru_Akilu#cite_ref-Balogun_7-0
- ↑ Agbese, Dan. Ibrahim Babangida: The Military, Power and Politic.https://en.wikipedia.org/wiki/Haliru_Akilu#cite_ref-Agbese_8-0
- ↑ Agbese, Dan. Ibrahim Babangida: The Military, Power and Politics.https://en.wikipedia.org/wiki/Haliru_Akilu#cite_ref-Agbese-2_9-0
- ↑ https://beegeagle.wordpress.com/2010/04/06/one-scarcely-known-reason-why-ibb-and-akilu-are-so-close/