Hameed Adewale
Ìrísí
Hameed Adewale Waheed | |
|---|---|
| Member of the House of Representatives of Nigeria for Agege constituency | |
| In office 2023–2027 | |
| Asíwájú | Samuel Babatunde Adejare |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressives Congress (Nigeria) (APC) |
Hameed Adewale jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú àgbègbè gege ni ilé igbimọ aṣòfin ìjọba àpapò láti ìpínlè Ẹ̀kọ́.[1][2] Adewale ni wọ́n dibo yàn sì ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà ni ọdún 2023 láti lọ sójú ẹkùn idibo Agege ni ilé igbimọ aṣòfin apapọ láti ìpínlè ẹ̀kọ́ nígbà tí ó jawe olú borí pẹlu ìbò 27,445 láti fi èyìn akegbe rẹ Sola Osolana tí ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party lélẹ̀ ẹniti òní ìbò 13,379.[3]
Itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Ogunseyin (2024-10-31). "House of Reps passes bill to increase retirement age of health workers to 65". The Guardian Nigeria News. Retrieved 2024-12-10. Text "firs" ignored (help); Unknown parameter
|Ẹ̀kọ́ t=ignored (help) - ↑ Yakubu, Dirisu (2024-10-08). "Lawmakers move to boost NOA's budget for effective re-orientation". Punch Newspapers. Retrieved 2024-12-10.
- ↑ Nwafor (2023-02-26). "APC wins Agege Federal Constituency seat in Lagos". Vanguard News. Retrieved 2024-12-10.
Àwọn ẹ̀ka:
- Pages with citations using unnamed parameters
- Pages with citations using unsupported parameters
- Living people
- Members of the House of Representatives (Nigeria) from Lagos State
- Members of the 10th National Assembly (Nigeria)
- All Progressives Congress members of the House of Representatives (Nigeria)
- Year of birth missing (living people)