Jump to content

Hameed Adewale

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Hameed Adewale Waheed
Member of the House of Representatives of Nigeria for Agege constituency
In office
2023–2027
AsíwájúSamuel Babatunde Adejare
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressives Congress (Nigeria) (APC)

Hameed Adewale jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú àgbègbè gege ni ilé igbimọ aṣòfin ìjọba àpapò láti ìpínlè Ẹ̀kọ́.[1][2] Adewale ni wọ́n dibo yàn sì ilé igbimọ aṣòfin àgbà orílè-èdè Nàìjíríà ni ọdún 2023 láti lọ sójú ẹkùn idibo Agege ni ilé igbimọ aṣòfin apapọ láti ìpínlè ẹ̀kọ́ nígbà tí ó jawe olú borí pẹlu ìbò 27,445 láti fi èyìn akegbe rẹ Sola Osolana tí ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party lélẹ̀ ẹniti òní ìbò 13,379.[3]

  1. Ogunseyin (2024-10-31). "House of Reps passes bill to increase retirement age of health workers to 65". The Guardian Nigeria News. Retrieved 2024-12-10. Text "firs" ignored (help); Unknown parameter |Ẹ̀kọ́ t= ignored (help)
  2. Yakubu, Dirisu (2024-10-08). "Lawmakers move to boost NOA's budget for effective re-orientation". Punch Newspapers. Retrieved 2024-12-10.
  3. Nwafor (2023-02-26). "APC wins Agege Federal Constituency seat in Lagos". Vanguard News. Retrieved 2024-12-10.

Àdàkọ:Lagos-politician-stub