Jump to content

Ibrahim Musa Gusau

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Ibrahim Musa Gusau
Official portrait, 2022
President of the Nigeria Football Federation
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
11 October 2022
AsíwájúAmaju Pinnick
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí
Ibrahim Musa Gusau

1 Oṣù Kẹta 1964 (1964-03-01) (ọmọ ọdún 61)
Zamfara State, Nigeria
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Àwọn ọmọ7
ResidenceNigeria
Occupation
  • Football administrator
  • Accountant

Ibrahim Musa Gusau (ti a bi ní ọjọ kínní oṣù kẹta ọdún 1964) [1] jẹ olùdarí eré ìdárayá lorilẹ-ede Naijiria, ti o ti ṣiṣẹ gẹ́gẹ́bí ààrẹ Ẹgbẹ Bọọlu afẹsẹgba Naijiria (NFF) láti ọdún 2022. O jẹ alága tẹlẹ rí ti Federation Athletics Federation of Nigeria (AFN), [2] alága tẹlẹ rí ti Ẹgbẹ Bọọlu Zamfara, ọmọ ẹgbẹ igbimọ ti Confederation of African Footballizing (CAF), ati ọmọ ẹgbẹ igbimọ ti CAF .

Apejọ idibo kejidinlọgọrin ti ajọ agbábọ́ọlu Nàìjíríà ti yán an gẹgẹ bi ààrẹ ogójì 40th ti àjọ náà ati arọ́pò fún Amaju Pinnick . [3] [4] [5] [6]

Gusau ṣiṣẹ gẹgẹ bi alága ẹgbẹ agbábọ́ọlu nipinlẹ Zamfara o si ti ṣiṣẹ gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ CAF ti Igbimọ Organizing Committee fún ìdíje Àwọn orílẹ-èdè Afirika. [7] [8]

Ni ọgbọ̀njọ́ Oṣu Kẹsan, ọdún 2022, Gusau ni a yán gẹgẹbi ààrẹ Ẹgbẹ agbábọ́ọlu afẹsẹgba Nàìjíríà lakoko Àpéjọ Gbogboògbò Ọdọọdun ẹlẹ́ẹ́kejìdínlọ́gọ́rin NFF ti o wáyé ni Ìlú Benin, Ipinlẹ̀ Edo . [9] [10]