Ibrahim Zakzaky
| Ayatollah Sheikh Ibraheem Zakzaky | |
|---|---|
Ibraheem Zakzaky in 2013 | |
| Ọjọ́ìbí | 5 Oṣù Kàrún 1953 Zaria, British Nigeria |
| Orílẹ̀-èdè | Nàìjíríà |
| Orúkọ míràn | Sharfuddeen |
| Ẹ̀kọ́ | Eto Iṣowo |
| Iléẹ̀kọ́ gíga | Ahmadu Bello University |
| Ìgbà iṣẹ́ | 1979–present |
| Gbajúmọ̀ fún | Founder of Islamic Movement in Nigeria |
| Olólùfẹ́ | Zeenatuddeen Ibraheem |
| Àwọn ọmọ | |
| Àwọn olùbátan | Sayyid Badamasi Yaqoub |
Ibraheem Yaqoub El-ZakzakyÀdàkọ:Pronunciation (alternately Ibraheem Zakzaky, Ibrahim Al-Zakzaky; won bí ni 5 May 1953) o jẹ ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà olórí ẹṣin. gbajúmò àti gbà jù gbá jà òní imon Shi'a tí o sì jẹ oga adarí wọn ní orílè-èdè Nàìjíríà, wòn tí tí mò ahamo fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà fún àwọn ohùn tí ohùn rí wípé ko bójú mú àti wípé ìtì mọ́lẹ̀ ohùn jẹ ọ̀nà àìtó, ni pàápàá jù lọ ìwà ajé banu àti jẹ gùdù jẹ rà ní orílè-èdè Nàìjíríà. Zakzaky ni gbagbọ wípé ẹṣin Islam àti ẹ̀kọ́ nípa rẹ nìkan lò lè mú ọna àbáyọ sì gbogbo ìdojúkọ ni eka ètò ìṣe ìjọba òṣèlú ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ni èyítí o jẹ wípé o fà ifaseyin tí o bá ìlọsíwájú orílè-èdè náà fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ti o tí pé sẹ́yìn. [3][4] nínú idanilekoo rẹ kàn láti ṣe ayẹyẹ fún Sheikh Uthman Bn Fodio ní (May 2023) èyítí àwọn ìjọ Academic Forum of Islamic Movement se agbakerure, Zakzaky je kò di mimọ wípé ìpolongo esin ohùn yíò ma tẹsiwaju lèyí tí Uthman Bn Fodio lànà rẹ kalẹ láti rí dájú wípé Islam jẹ ẹṣin tí o má dárí ìṣàkóso ìjọba ni Nàìjíríà àti ni gbogbo ilé iwo ọrùn Áfíríkà. Ọkàn lára àwọn idanilekoo rẹ tí otún w'aye ní ìlú Sokoko bákannáà ni (20 May 2023), ọkàn lára àwọn oníwàásù rẹ, Dr. Nasir Hashim so wípé àlá Zakzaky’s ohùn nìkan ni ona àbáyọ ti o kú fún ilé Áfíríkà. Sheikh Zakzaky jẹ olórí àwọn ìjọ Islamic Movement, ni èyítí o dasile ní ọdún 1970s, lákòókò tí o jẹ akeko ni ilé ìwé Ahmadu Bello University, láti ma ṣe ìpolongo fún Shia Islam láàrin ọdún 1979, lákòókò ogún orílè-èdè Ìran —ni èyítí o mú òpin dé bá jíjẹ ọba ní orílè-èdè náà ti iko ìjọ Mùsùlùmí sì gbà ìjọba orílẹ̀ èdè lábé àṣẹ olùdarí Ayatollah Khomeini. Zakzaky ní gbàgbó wípé àti gbá ìjọba irú rẹ ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti àwọn àgbègbè yíò rọrùn láti ṣe. Ìjọba ti fí sì ahamo lọpọlọpọ ìgbà fún ìwà i dá omi àlàáfíà ìlú rú látàrí àwọn igbese àti isesi rẹ láwùjọ lábé ìjọba ológun ni orílè-èdè Nàìjíríà láàrin ọdún 1980s si ọdún 1990s, ti ijọba orílè-èdè sì fí o jù sole fún láti mọ ṣe amojuto àwọn igbese rẹ láti jẹ kí àlàáfíà jọba.[4] Ni Oṣu kejìlá ọdún 2015, àwọn ọmọ ogún orílè-èdè Nàìjíríà lọ sí ilé rẹ ní Zaria, ti wọn si ṣe léṣe, tí wósì pá ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn alatele rẹ. Láti ìgbà náà, ni ọtí wá ní akolo ìjọba àpapọ̀ leyin ìgbà tí wọ́n dasile láti ahamo, ni itẹle òfin ọdún 2016.[5][6] Ni ọdun 2019, kóòtù ní ìpínlè Kaduna dasile láti lọ gbá itọju lókè òkun pẹ̀lú ìyàwó rè ṣùgbọ́n wọn padà dé láti ìlú India leyin ọjọ́ kẹta India látàrí wípé kò sì itọju to pé yẹ àti ifi ọwọ ti o lè mú wọn láti ọwọ àwọn èso abo si wọn ṣe alábòójútó ọgbà ilé ìwòsàn náà[7]
Ìgbésí ayé àti ẹ̀kọ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ibraheem ni wọ́n be ni 5 May ọdún 1953 (15 Sha’ban 1372 AH), ni ìlúZaria, Kaduna State. O losi ilẹ̀ ìwé Provincial Arabic School, Zaria (1969-1970), ilé-ìwé nípa ẹkọ Lárúbáwá, ni ìlú Kano láàrín ọdún 1971-1976, ni bí tí ọtí gbà ìwé ẹ̀rí ‘Grade II’, àti ilé ìwé Ahmadu Bello University (ABU), Zaria (1976-1979), ni bí tí o tí kàwé gbà degree nípa ẹkọ ọ̀rọ̀ ajé. ìwé ẹ̀rí ní àwọn aláṣẹ ilé ìwé rẹ kò fún látàrí àwọn akitiyan nípa ẹṣin.[8] Lákòókò ìgbà tí o fí wá ní ilé ẹ̀kọ́ náà gẹgẹbi akeko, o jẹ òníyanjú tí o sì ni akíkanjú laarin awọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n pé ìpè sì ojú ọna ẹṣin, ti òsì padà wádìí akọwe àgbà fún ẹgbẹ olú pẹpẹ sì ẹṣin Islam láàrin awọn akẹ́kọ̀ọ́ Muslim Students Society of Nigeria (MSSN) nínú ọgbà ilé ẹ̀kọ́ náà (1977/78), leyin náà odi ìgbà kejì aree ẹgbẹ náà (International Affairs) of the National Body of the MSSN in 1979.[9]

The same year, he is said to have become impressed with the 1979 Iranian Revolution and wanted to emmulate it at home. Later, Zakzaky went to Iran, ultimately becoming a Shia. At home, he became the leader of the Islamic Movement in Nigeria and used it as a way to proselytize and gain followers in the 1990s. As a result of his activities, a significant number of people have converted to Shia Islam in a country once with hardly any Shia population.[10]
Islamic Movement Ni Orílè-èdè Nàìjíríà
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ibraheem Zakzaky jẹ́ ọ̀kan gbogì àti adarí èmi ti ìjọ Islamic Movement in Nigeria (ti o fí gbà kàn jẹ: Muslim Brothers[11]), Ìjọ ti Mùsùlùmí Shi'a ti o gbajumo julọ. Nínú àwọn ènìyàn bí 180 mílíọ̀nù, idà méjì wo niMùsùlùmí, ida pẹrẹte ni o jẹ ọmọ ẹgbẹ Shi'a Islam. Nínú ìṣe ìwádìí Nnamdi Obasi, Oga àgbà àwọn tí wọ́n ṣe yiyanana nkan ni orílè-èdè Nàìjíríà ti International Crisis Group (ICG), afo jù sún ẹgbẹ IMN's pín sí méjì: “Láti rí aridaju àmúlò ẹka ètò idajọ òfin ẹṣin Islam...àti dídá orílẹ̀èdè tí Mùsùlùmí kalẹ.”[12] Dr Iqbal Siddiqui ṣe àpèjúwe El-Zakzaky gẹgẹbi "the de facto leader tí Islamic Movement ni orílè-èdè Nàìjíríà".[13]
Israel
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]ègbè Resource Forum fún Islamic Movement ti orílè-èdè Nàìjíríà (IMN) se idanilekoo lórí "Dídá orílè-èdè Israeli kalẹ lọ́nà ìtó" ni Arewa House ni Ìpínlẹ̀ Kaduna ni 21 May ọdún 2008. Zakzaky wípé,nígbà ti orílè-èdè Israeli se ajọdunàádọ́ta ọdún lórí ilẹ̀ Palestine', a wá n ṣe òfò nítorí wípé òtítọ́ ibè ni wípé ohùn tí kì bá ṣe tẹ́nì kólé jẹ́ tẹ́nì bí Israel se fi ìwà janduku gbà ilé òní ile, kò sì bí ọ̀sẹ̀ lè pé tó oloruka yíò gbà òrùka rẹ ji ojú yíò sì ti aw alati lẹ́yì wọn ti won kun wọn lọ́wọ́ láti mú Palestine's si ìgbèkùn. Israel yio do jù dé pẹ̀lú àwọn àlá tí lẹ́yìn wọn o da mí lójú.[14]
Ìṣe akọlù àwọn ọmọ ológun sì iko re
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Zaria Quds Day Massacre
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]On Friday 25 July 2014, the Nigerian Army reportedly fatally shot 35 followers of Ibraheem Zakzaky, including three of his sons,[15] after a pro-Palestinian procession in Zaria. The British Islamic Human Rights Commission published the report Zaria Massacres and the Role of the Military in October 2014.[16]
Ipaniyan ti ọdún 2015 ni ìlú Zaria
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Sheikh al-Zakzaky ni wọ́n ṣe ni ẹsẹ ti wọn sì ti mọ́lẹ̀ pẹlu ìyàwó re, ni ọdun 2015 Zaria massacre, ni bìtì mẹta nínú awọn ọmọ rẹ to kú ti se alabapade ikú wọ́n, ọpọlọpọ awọn ọkọ awọn ọmọ lẹ́yìn rẹ ni àwọn ọmọ ológun orílè-èdè Nàìjíríà se ikú pá.
Ahamo àti itu sílè
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Gẹgẹbi ìdájọ́ kóòtù àgbà ni Nàìjíríà ni ọjọ 2 December ọdún 2016, Ibraheem Yaqoub El Zakzaky niile-ẹjọ pàṣẹ fún wípé kí wọn tú sílè kúrò lọ́wọ́ àwọn èso ààbò Department of State Services láàrin ọjọ 45. El Zakzaky àti ìyàwó rè kí ìjọba sì sàn owó tí o tó 50 million Naira ($164,052) fun owó gbà mon bínú. Adajo náà so wípé láti ti mọ́lẹ̀ látàrí wípé o dáàbò bò àràẹni "holding him for his own protection" ko tó nítorí.[6] ni 16 January ọdún 2017, Amnesty International bèrè wípé kí ìjọba àpapọ̀ orílè èdèNàìjíríà tú Zakzaky àti ìyàwó sílè ni ìbámú pẹ̀lú ìdájọ́ ilé ejò."[17] Ni 13 January ọdún 2018, Zakzaky, ni wọn ti mọ́lẹ̀ níbi ti ẹnikẹni omo láì je. ko jejo kánkán láti December ọdún 2015, wọn je kò jáde farahàn ranpe láàrin ọdún méjì, ti wọn ko sì gbá láyé láti rí doctor.[18] Láti ọdún 2014, Zakzaky wá ní ahamo ijoba apapo pẹlu àjọṣe àti imosi ìjọba ìpínlè Kaduna [19][20] fun ẹ̀sùn ọ̀daràn.[21] Láti ìgbà náà, àwọn ọmọ lẹ́yì rẹ ṣe iwode láti fi bèrè fún ìdásílẹ̀ rẹ la ahamo.[22] I tí ní mọ́lẹ̀ fún ìgbà ti o pé láì je jọ takò òfin orílẹ̀èdè Nàìjíríà.[23]

2019 clashes
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ni 22 January ọdún 2019, Zakzaky àti ìyàwó rè, Zeenat lọ sí kóòtù gíga ti ìlú Kaduna láti lọ ṣe igbejọ fún idasile wọn ni ọgbà àti mọ́lẹ̀. Àwọnèso ààbò tí wọ́n pọ láti dáàbò bò wọn.[24] Ni July ọdún 2019, láti bẹ̀rẹ̀ fún itusile Ibraheem el-Zakzaky, ègbé lè gbé àwọn ènìyàn ni wọ́n dúró sí ìta ilé ìjọba ti àwọn èso ààbò sí gbìyànjú láti tu wọnká pẹlu yìnyín ìbon sókè láti tu wọnká. Nínú rògbòdìyàn náà ènìyàn méjì kú ti awọn ènìyàn 40 nínú àwọn ti wọn ṣe ifi ehonu hàn ni àwọn agbófinró mu sí ati mọ́lẹ̀. Ìgbìmọ̀ Islamic Movement ti Nàìjíríà (IMN), je àwùjọ àwọn Shia Muslims, so wípé iwode yìí má te síwájú títí ti won fi dá el-Zakzaky sílè. Abdullahi Murtala, ẹniti òjé ọjọgbọn nípa ètò ààbò, "Shia Muslims jẹ àwùjọc ti wọn rí 'bi iyanje ti wọn yo sí má se iwode láti fi ṣe àtakò sì ìjọba Buhari".[25] [26] Ìjà mí bẹ sílè láàrin wọn pẹlu Ọlọpa ni on 22 July ti ọpọlọpọ awọn a fí eho nù hàn si rí ikú lọ́wọ́ èso ààbò, Ọlọpa àti ọdọ ọmọdé akọròyìn, Precious Owolabi láti NYSC. Igbákejì kọmiṣanna Ọlọpa náà kú.[27][28] ìjọba Muhammadu Buhari ṣé àpèjúwe wọn bí àwọn ẹgbẹ tí kò tẹ́lẹ̀ òfin mún lẹ́yìn ìpàdé pẹlu oga èso ààbò orílè-èdè Nàìjíríà.[29][30]
Ìgbésí ayé
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]O ṣé ìgbéyàwó pẹlu Zeenah Ibraheem, ti o sì bí ọmọ Mẹsan fún.[31] ṣùgbọ́n, mẹta loku ọkùnrin kàn obìnrin méjì. Mẹta nínú awọn ọmọ rẹ ni wọ́n se kú pá niZaria Quds Day massacres in ọdún 2014.[5] Wo n tún ṣe ikú pá mẹta mìíràn ni ọdun 2015 Zaria massacre.[2] Wọn sọ wípé òkú ni 12 December ọdún 2022 ni ọmọ ọdún 69, ṣùgbọ́n ìwádìí fìdí re múlẹ̀ wípé ìró ni ko kú.[32]
See also
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]References
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- 1 2 3 "Sheikh Zakzaky's 3 sons, 9 others died in Nigerian troops, Shiite Muslims Clash". Vanguard Newspaper. Archived from the original on 4 March 2016. Retrieved 13 April 2016. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - 1 2 3 4 "Three sons of Zakzaky killed in Nigeria massacre: Rights group". Press TV. Archived from the original on 20 April 2016. Retrieved 13 April 2016. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Dan Issacs (1 October 2001). "Nigeria's firebrand Muslim leader". BBC News. Archived from the original on 26 January 2020. Retrieved 28 February 2014. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - 1 2 Connor Gaffey (16 December 2015). "Who is Sheikh Zakzaky, Nigeria's Most Powerful Shiite Muslim?". Newsweek Magazine. Archived from the original on 8 September 2021. Retrieved 12 April 2016. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - 1 2 "Family Of Sheikh Zakzaky Unclear If He Is Dead Or Unwell, According To Family Sources". Sahara Reporters. 17 Dec 2015. http://saharareporters.com/2015/12/17/family-sheikh-zakzaky-unclear-if-he-dead-or-unwell-according-family-sources.
- 1 2 "Court orders DSS to release Shiite leader, pay him N50M compensation". Pulse Nigeria. 2 December 2016. Archived from the original on 9 July 2020. Retrieved 2 October 2020. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Nigerian Shia leader, wife reject treatment in India, return home". www.aljazeera.com. Archived from the original on 8 September 2021. Retrieved 2 October 2020. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Biography of Mu'allim Ibrahim Al-Zakzaky". Bregava.tripod.com. Archived from the original on 3 June 2011. Retrieved 2011-03-20. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Official Website Of The Islamic Movement In Nigeria". Islamicmovement.org. 1953-05-05. Archived from the original on 2011-02-26. Retrieved 2011-03-20. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "As Trump Makes Threats, Iran Makes Friends". Bloomberg. 8 March 2017. Archived from the original on 8 March 2017. Retrieved 8 March 2017. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Michael Olufemi Sodipo (2013). "Mitigating Radicalism in Northern Nigeria" (PDF). p. 3. Archived from the original (PDF) on 19 January 2016. Retrieved 12 April 2016. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Who is Sheikh Ibrahim Zakzaky?". Newsweek Magazine. Archived from the original on 8 September 2021. Retrieved 12 April 2016. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Archived 19 November 2006 at the Wayback Machine.
- ↑ "Nigeria: Israeli State Would Crumble, Says Zakzaky". 21 May 2008. Archived from the original on 12 October 2012. Retrieved 25 October 2009 – via AllAfrica. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Punch Newspaper. "Soldiers killed three Elzakzaky sons, 32 others.". Archived from the original on 27 July 2014. Retrieved 10 April 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "IHRC. Zaria Quds Massacre: The role of the Military". IHRC United Kingdom. October 2014. Archived from the original on 3 April 2015. Retrieved 15 April 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Nigeria: Comply with court order to release Sheik Ibraheem El-Zakzaky Archived 16 August 2019 at the Wayback Machine., 16 January 2017, Amnesty
- ↑ "Nigerian Shi'ite leader, rumoured dead, makes first public appearance in two years". Reuters. 13 January 2018. Archived from the original on 13 January 2018. Retrieved 13 January 2018. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Shiite leader El-Zakzaky brought to court, charged with murder - Premium Times Nigeria" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2018-05-15. Archived from the original on 2 March 2020. Retrieved 2020-03-02. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Eight-count charge filed against Shiite leader, El-Zakzaky". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2018-04-27. Archived from the original on 2 March 2020. Retrieved 2020-03-02. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Why we never release El Zakzaky - Presidency". BBC News Pidgin. 2019-07-23. https://www.bbc.com/pidgin/tori-49069376.
- ↑ "Reflection-Online - The official site of the Free Zakzaky Campaign". Reflection-Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2 March 2020. Retrieved 2020-03-02. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Nigeria is Violating Constitution on the El-Zakzaky and Dasuki Cases | Abdullah Tijani". African Liberty (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-07-22. Archived from the original on 2 March 2020. Retrieved 2020-03-02. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Updated: Heavy security as El-Zakzaky, wife head to court in Kaduna". Oak TV Newstrack (oak tv). 22 January 2019. Archived from the original on 22 January 2019. https://web.archive.org/web/20190122130211/https://oak.tv/newstrack/heavy-security-el-zakzaky-wife/.
- ↑ "Nigeria's Shia Muslims continue protest over el-Zakzaky detention". aljazeera. Archived from the original on 11 July 2019. Retrieved 11 July 2019. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Nigerian parliament: Violent clashes at Shia protest". bbc. Archived from the original on 10 July 2019. Retrieved 9 July 2019. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Bello, Raphel (2019-07-23). "How Deputy CP, reporter died during Shi'ites protest" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 23 July 2019. Retrieved 2019-07-23. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Alejoh, Daniel (2019-07-23). "Police kill 11 of our members ---IMN" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 23 July 2019. Retrieved 2019-07-23. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Adeniyi, Olakunle (2019-07-23). "Breaking: Buhari to proscribe IMN Shi'ites "to put end to madness"". Nigeria News | FellowPress.com (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 23 July 2019. Retrieved 2019-07-23. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Press, Fellow (2019-07-27). "Breaking: Court proscribes Shiites terrorists". Nigeria News | FellowPress.com (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 30 July 2019. Retrieved 2019-07-30. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Biography of Sheikh Zakzaky". Official Website of the Islamic Movement of Nigeria. 18 September 2013. Archived from the original on 22 December 2015. Retrieved 20 December 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "شیخ ابراہیم زکزاکی کے انتقال کی خبر صرف ایک افواہ ہے". 12 December 2022. Archived from the original on 4 December 2023. Retrieved 10 July 2025.
External links
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]| Wikimedia Commons ní àwọn amóunmáwòrán bíbátan mọ́: Ibrahim Zakzaky |
- Official website Archived 30 March 2018 at the Wayback Machine. of the Islamic Movement (Nigeria)
- Islamic Movement In Nigeria
- Biography at Tripod
- Pages with citations using unsupported parameters
- Pages containing cite templates with deprecated parameters
- Webarchive template wayback links
- CS1 Èdè Gẹ̀ẹ́sì-language sources (en)
- Use British English from October 2020
- Articles with invalid date parameter in template
- All Wikipedia articles written in British English
- 1953 births
- Nigerian Shia clerics
- Nigerian Shia Muslims
- Converts to Shia Islam from Sunni Islam
- Critics of Sunni Islam
- Living people
- People from Zaria
- Ahmadu Bello University alumni
- People from Kaduna State
- Nigerian Muslim activists
- Qutbists