Ilé-iṣẹ́ Òye Ààbò Ológun (Orílè-èdè Nàìjíríà)
Ile-isẹ òye ààbò ológun (DIA), jẹ ile-iṣẹ ìpìlẹ̀ fun Òye ologun ti ilẹ Nàìjíríà. DIA jẹ didasilẹ ni ọdun 1986 lati pese eto ti o munadoko nipa gbigba oye -iṣe-alamì- fún jijagun ati aabo fun Awọn ọmọ-ogun Naijiria ati Ile-iṣẹ Aabo . [1] DIA n ṣe agbega Ilana Aabo Naijiria, gbe ifowosowopo ologun pẹlu awọn orilẹ-ede miiran larugẹ, oṣe aabo fún igbesi aye awọn ara ilu Naijiria, o sí iduroṣinṣin lati ṣetọju aala ilẹ Nàìjíríà. DIA ni olori nipasẹ Chief of Defence Intelligence (CDI) ti Aare Nigeria maun yàn.
Awọn ipilẹṣẹ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ni oṣu kẹfa, ọdun 1986, aarẹ nigba naa, ọgagun Ibrahim Babangida gbe aṣẹ Nọmba 19 jade. Lati tu Ajọ Aabo Orilẹ-ede (NSO) ki wọn sì ṣe atunto awọn iṣẹ aabo orile-ede Naijiria si awọn isọri mẹta ọtọọtọ labẹ Ọfiisi ti Alakoso Aabo Orilẹ-ede. [2]
- Ile-iṣẹ Aabo Ilu (SSS) jẹ iduro fun Òye ààbò abẹ̀lè pẹlu Oludari Gbogbogbo Ismaila Gwarzo ati Igbakeji Oludari Lt Col AK Togun .
- Àjọ ti òye ti Orilẹ-ede (NIA) ṣe itọju oye ti o tayọ ala orile-ede ati ṣiṣe ìtakò Ise alamì sí orile-ede.
- DIA ni wọn fi sọri àwọn òye ti o ni ibatan pẹlu ológun ni ita ati inu Naijiria
Awọn olori fún Ile-iṣẹ Òye Ààbò Ológun
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ile-ẹkọ giga fun Òye Ààbò Ológun
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ile-ẹkọ giga fun Òye Aabo ologun (DIC) je didasilẹ nipasẹ Ofin 19 ti 1986 gẹgẹ bi apa ikẹkọ ti Ile-iṣẹ òye Aabo (DIA). Lati igbanna, o ti dagba lati di ààyè àmúyangàn ni agbegbe wa; Paapaa laarin Àgbájọ Tòkòwò àwọn Orílẹ̀-èdè Iwọ-oorun Afirika (ECOWAS). [3]
- http://www.dia.gov.ng/ Archived 2023-08-06 at the Wayback Machine. Archived
- https://fas.org/irp/world/nigeria/dia.htm Archived 2016-08-07 at the Wayback Machine.