Israel Oludotun Ransome-Kuti
| Israel Oludotun Ransome-Kuti | |
|---|---|
Reverend Israel àti olóyè Funmilayo lẹ́gbẹ́ rẹ, Dolu wà lẹyìn àti Fela ní ilẹlẹ ni wájú, Beko ni ọmọ ti wọn gbè dání, Olikoye lo wà ni apá ọtún | |
| Ọjọ́ìbí | 30 Oṣù Kẹrin 1891 Abeokuta, ipinlẹ Ogun, Nàìjíríà |
| Aláìsí | 6 April 1955 (ọmọ ọdún 63) Abeokuta, Nàìjíríà |
| Orílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Iléẹ̀kọ́ gíga | Fourah Bay College CMS Grammar School, Lagos |
| Iṣẹ́ | |
| Ìgbà iṣẹ́ | 1916–1954 |
| Olólùfẹ́ | Àdàkọ:Ìyàwó rẹ |
| Àwọn ọmọ | 4
Olikoye Ransome-Kuti Deceased
Olufela Olusegun Oludotun Ransome-Kuti Deceased Beko Ransome-Kuti Deceased Dolupo Ransome-Kuti[citation needed] |
| Parent(s) | Josiah Ransome-Kuti Amy Bertha Arinola Ransome-Kuti (Née Olubi) |
| Notes | |
Israel Oludotun Ransome-Kuti Ní ààrẹ akọ́kọ́ Nigeria Union of Teachers[1] | |
Israel Oludotun Ransome-Kuti (ọgbọ̀njọ́ oṣù kẹrin ọdún 1891 – ọjọ kẹfà oṣù kẹrin ọdún 1955) [2] jẹ olùkọ ọmọ Nàìjíríà. [3]
Ìgbésí ayé
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]A bí Israeli ni ọgbọ̀njọ́ oṣù Kẹrin ọdún 1891 ni Abeokuta, Ipinle Ogun si ìdílé Josiah Ransome-Kuti ati Bertha Anny Olubi. O pari ẹkọ alákọ́bẹ̀rẹ̀ àti gíràmà ní Lagos Grammar School àti Abeokuta Grammar School ki o to lo si Fourah Bay College, Freetown níbi ti o ti parí eko gboyè. [4]
Nígbàtí o jáde ní Fourah Bay College, Israel padà sí Nàìjíríà ní ọdún 1916 láti bẹrẹ iṣẹ rẹ àkọ́kọ́ gẹgẹbi olùkọ kílásì ni Abéòkúta Grammar School títí di ọdún 1918 nígbàtí o fi ìlú rẹ̀ sílẹ̀. [5] Wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bí ọ̀gá àgbà ilé ẹ̀kọ́ Gírámà Ìjẹ̀bú Ode fún ọdún mẹ́tàlá, ó sì tẹ̀ síwájú láti dá ẹgbẹ́ ọ̀gá àgbà ilé ẹ̀kọ́ Ìjẹ̀bú sílẹ̀ lọ́dún 1926. [ <span title="This claim needs references to reliable sources. (April 2022)">Ti o nilo itọkasi</span> ]
Ni ọdún 1931, wọn yán Israel gẹgẹbi Ààrẹ Alàkóso ti Nigeria Union of Teachers ti wọn ṣẹṣẹ dasilẹ, [6] ipò ti o wà titi dì ìgbà ti o fẹhinti ni ọdún 1954. Gbọ̀ngán Kuti , ọkàn nínú àwọn gbọngàn ibùgbé ní Fasiti ìlú Ibadan ti wọn ṣii ni ọdún 1954, ni orukọ rẹ láti bu olá fún. [7]
Ìgbésí ayé ara ẹni
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ransome-Kuti ní bàbá olórin Fẹla Kuti, àti Oníṣègùn Olikoye Ransome-Kuti ati Beko Ransome-Kuti . O je bàbá bàbá olórin Seun Kuti .
Ikú
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ní ọjọ kẹfà oṣù kẹrin ọdún 1955 ni Israel ku lóri àisàn tó jẹmọ́ jẹjẹrẹ kàn ní ilè rẹ tó wà ní Abeokuta, ìpínlẹ̀ Ogun. [8]
Ìwe àkọsílẹ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Raymond J. Smyke; Denis C. Storer (1974). Nigeria Union of Teachers: An Official History. Oxford University Press. https://books.google.com/books?id=P7G0AAAAIAAJ.
- ↑ .https://books.google.com/books?id=P7G0AAAAIAAJ
- ↑ .https://books.google.com/books?id=fc-QAAAAQBAJ&pg=PT241
- ↑ https://books.google.com/books?id=8gsOAQAAMAAJ
- ↑ https://books.google.com/books?id=-MZtAAAAMAAJ
- ↑ https://en.wikipedia.org/wiki/Israel_Oludotun_Ransome-Kuti#cite_ref-5
- ↑ https://web.archive.org/web/20200926145650/http://nut-nigeria.org/index.php/2016-01-08-15-02-20/origin-of-nut
- ↑ https://web.archive.org/web/20160304100441/http://ui.edu.ng/hallsofresidence