Jide Awobana
| Jide Awobona | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | Babajide Saheed Awobona 9 Oṣù Kejì 1985 Lagos state |
| Orílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Iléẹ̀kọ́ gíga | Olabisi Onabanjo University |
| Iṣẹ́ | |
| Ìgbà iṣẹ́ | 2002–present |
Babajide Saheed "Jide" Awobona
Listen ti won bi ni ojo kesan-an osu keji odun 1985) je osere Naijiria,[1] jẹ́ akọ̀wé eré àti olùdarí fíìmù. Wọ́n bí won si tọ́ ọ dàgbà ní Èkó, ṣùgbọ́n ó jẹ́ ọmọ ìpínlẹ̀ Ògùn. Ó di ẹni tó gbajúmọ̀ fún ipa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Sam nínú eré àwàdà Jenifa's Diary.
Ẹ̀kọ́ ré
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Jide Awobona lọ sí ilé-ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ Wesley Memorial ní Ìpínlẹ̀ Èkó. Lẹ́yìn ìyẹn, ó lọ sí ilé-ìwé gíga Amuwo Odofin, lẹ́yìn náà ló gba oyè Bachelor of Arts nínu Ìmọ̀ Ìbánisọ̀rọ̀ Lágbádá láti ile-ekó giga Olabisi Onabanjo ní Ìpínlẹ̀ Ògùn.
Ísé re
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Jide Awobona bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí òṣèré ní ọdún 2002, ọdún kan náà ló bẹ̀rẹ̀ ìdánilẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ nípa iṣẹ́ òṣèré pẹ̀lú ilé-iṣẹ́ Jovies Perfection Press.[2] Wọ́n bẹ̀rẹ̀ si mo ní ọdún 2003 nígbà tó kó ipa pàtàkì nínú eré tẹlifíṣọ̀n tí ó gbajúmọ̀ ní Nàìjíríà, Super Story, Last Honor.[3] Láti ìgbà náà, ó ti kópa, ó sì ti ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ fíìmù Nàìjíríà. Wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bí Aṣagbátà Tó Dára Jù nínu Ipa pàtàkì (Yorùbá) nípasẹ̀ àwọn àmì-ẹ̀yẹ BON ní ọdún 2020. [4][5]
Àwọn fíìmù tí ó ti ṣiṣẹ́ lórí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- Jenifa's Diary (2013) bi Sam
- The Bunglers (2017) bi Alhaji
- Ranti Mi (2018) bi Jide
- Convicted (2019)
- Olopa Olorun (2019)
- Alimi (2021) b Samuel
- Akaba (2021)
- The Cokers (2021) bi Bayo
- Clock (2019)
- Olokun (2021)[6][7]
- The Event (2017)[8][9]
- Olawura (2022) pelu Tierny Olalere[10]
- Lisabi: The Uprising (2024) bi Osobande
Àwọn Àmì-ẹ̀yẹ àti Àwọn Yíyàn
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]| Ọdún | Ìṣẹ̀lẹ̀ | Àmì-ẹ̀yẹ | Fíìmù | Ìyọrísí | Ìtọ́kasí |
|---|---|---|---|---|---|
| 2017 | Maya Awards Africa | Òṣèré tó dára jù nínú eré tẹlifíṣọ̀n (Jenifa's Diary) | N/A | Àdàkọ:Wọ́n jẹ́ olúborí | |
| 2020 | Àwọn àmì-ẹ̀yẹ BON 2020 | Òṣèré tó dára jù ní ipa pàtàkì (Yorùbá) | Ìwọ Ni Èmi | Àdàkọ:Wọ́n yàn án | "Ibrahim Yekini bọ́rí Lateef Adedimeji, àti àwọn mìíràn fún àmì-ẹ̀yẹ Òṣèré tó dára jù - P.M. News". pmnewsnigeria.com. Retrieved 2021-09-23.
"Àwọn àmì-ẹ̀yẹ BON ṣí àtòjọ àwọn yíyàn 2020". The Eagle Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-11-17. Retrieved 2021-09-23. |
Àwon Ítokási
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Jide Awobona (Actor) | Photo and Movies | INSIDENOLLY". www.insidenolly.ng (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 16 September 2021. Archived from the original on 16 September 2021. Retrieved 2021-09-16. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "I'm Not Comfortable With Gigolo Roles – Jide Awobona". Independent Newspaper Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 14 September 2019. Retrieved 2021-09-16.
- ↑ "I'm Not Comfortable With Gigolo Roles – Jide Awobona". Independent Newspaper Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 14 September 2019. Retrieved 2021-09-16.
- ↑ "2020 BON: Here are 5 nominees for 'Best Kiss' category" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-12-02. Retrieved 2021-09-16.
- ↑ BellaNaija.com (2020-11-16). "Temi Otedola, "Living In Bondage: Breaking Free", Kayode Kasum score BON Award 2020 Nominations". BellaNaija (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-09-16.
- ↑ BellaNaija.com (2021-02-17). "Starring Shaffy Bello, Femi Adebayo, Jide Awobona, Here's the Teaser + BTS for Forthcoming Epic Drama "Olokun"". BellaNaija (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-09-16.
- ↑ "Shaffy Bello leads in new Nollywood historical epic film 'Olokun'". Pulse Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-02-17. Retrieved 2021-09-16.
- ↑ The Event (Short 2017) – IMDb (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì), retrieved 2021-09-16
- ↑ "The Event". FilmFreeway (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-09-16.
- ↑ "Olawura (2022) | Drama". IMDb.