Jump to content

Jide Awobana

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Jide Awobona
Ọjọ́ìbíBabajide Saheed Awobona
9 Oṣù Kejì 1985 (1985-02-09) (ọmọ ọdún 40)
Lagos state
Orílẹ̀-èdèNigerian
Iléẹ̀kọ́ gígaOlabisi Onabanjo University
Iṣẹ́
Ìgbà iṣẹ́2002–present

Babajide Saheed "Jide" Awobona Yo-Babajide Saheed Awobona.ogg Listen ti won bi ni ojo kesan-an osu keji odun 1985) je osere Naijiria,[1] jẹ́ akọ̀wé eré àti olùdarí fíìmù. Wọ́n bí won si tọ́ ọ dàgbà ní Èkó, ṣùgbọ́n ó jẹ́ ọmọ ìpínlẹ̀ Ògùn. Ó di ẹni tó gbajúmọ̀ fún ipa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Sam nínú eré àwàdà Jenifa's Diary.

Jide Awobona lọ sí ilé-ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ Wesley Memorial ní Ìpínlẹ̀ Èkó. Lẹ́yìn ìyẹn, ó lọ sí ilé-ìwé gíga Amuwo Odofin, lẹ́yìn náà ló gba oyè Bachelor of Arts nínu Ìmọ̀ Ìbánisọ̀rọ̀ Lágbádá láti ile-ekó giga Olabisi Onabanjo ní Ìpínlẹ̀ Ògùn.

Jide Awobona bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí òṣèré ní ọdún 2002, ọdún kan náà ló bẹ̀rẹ̀ ìdánilẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ nípa iṣẹ́ òṣèré pẹ̀lú ilé-iṣẹ́ Jovies Perfection Press.[2] Wọ́n bẹ̀rẹ̀ si mo ní ọdún 2003 nígbà tó kó ipa pàtàkì nínú eré tẹlifíṣọ̀n tí ó gbajúmọ̀ ní Nàìjíríà, Super Story, Last Honor.[3] Láti ìgbà náà, ó ti kópa, ó sì ti ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ fíìmù Nàìjíríà. Wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bí Aṣagbátà Tó Dára Jù nínu Ipa pàtàkì (Yorùbá) nípasẹ̀ àwọn àmì-ẹ̀yẹ BON ní ọdún 2020. [4][5]

Àwọn fíìmù tí ó ti ṣiṣẹ́ lórí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  • Jenifa's Diary (2013) bi Sam
  • The Bunglers (2017) bi Alhaji
  • Ranti Mi (2018) bi Jide
  • Convicted (2019)
  • Olopa Olorun (2019)
  • Alimi (2021) b Samuel
  • Akaba (2021)
  • The Cokers (2021) bi Bayo
  • Clock (2019)
  • Olokun (2021)[6][7]
  • The Event (2017)[8][9]
  • Olawura (2022) pelu Tierny Olalere[10]
  • Lisabi: The Uprising (2024) bi Osobande

Àwọn Àmì-ẹ̀yẹ àti Àwọn Yíyàn

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
ỌdúnÌṣẹ̀lẹ̀Àmì-ẹ̀yẹFíìmùÌyọrísíÌtọ́kasí
2017Maya Awards AfricaÒṣèré tó dára jù nínú eré tẹlifíṣọ̀n (Jenifa's Diary)N/AÀdàkọ:Wọ́n jẹ́ olúborí
2020Àwọn àmì-ẹ̀yẹ BON 2020Òṣèré tó dára jù ní ipa pàtàkì (Yorùbá)Ìwọ Ni ÈmiÀdàkọ:Wọ́n yàn án"Ibrahim Yekini bọ́rí Lateef Adedimeji, àti àwọn mìíràn fún àmì-ẹ̀yẹ Òṣèré tó dára jù - P.M. News". pmnewsnigeria.com. Retrieved 2021-09-23. 

"Àwọn àmì-ẹ̀yẹ BON ṣí àtòjọ àwọn yíyàn 2020". The Eagle Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-11-17. Retrieved 2021-09-23. 

  1. "Jide Awobona (Actor) | Photo and Movies | INSIDENOLLY". www.insidenolly.ng (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 16 September 2021. Archived from the original on 16 September 2021. Retrieved 2021-09-16. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. "I'm Not Comfortable With Gigolo Roles – Jide Awobona". Independent Newspaper Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 14 September 2019. Retrieved 2021-09-16.
  3. "I'm Not Comfortable With Gigolo Roles – Jide Awobona". Independent Newspaper Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 14 September 2019. Retrieved 2021-09-16.
  4. "2020 BON: Here are 5 nominees for 'Best Kiss' category" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-12-02. Retrieved 2021-09-16.
  5. BellaNaija.com (2020-11-16). "Temi Otedola, "Living In Bondage: Breaking Free", Kayode Kasum score BON Award 2020 Nominations". BellaNaija (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-09-16.
  6. BellaNaija.com (2021-02-17). "Starring Shaffy Bello, Femi Adebayo, Jide Awobona, Here's the Teaser + BTS for Forthcoming Epic Drama "Olokun"". BellaNaija (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-09-16.
  7. "Shaffy Bello leads in new Nollywood historical epic film 'Olokun'". Pulse Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-02-17. Retrieved 2021-09-16.
  8. The Event (Short 2017) – IMDb (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì), retrieved 2021-09-16
  9. "The Event". FilmFreeway (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-09-16.
  10. "Olawura (2022) | Drama". IMDb.