Jude Ngaji
Ìrísí
Jude Ngaji je olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà . O jẹ ọmọ ẹgbẹ ti o nsójú àgbègbè Ogoja/Yala ni ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà ni orílè-èdè Nàìjíríà. [1] [2]
Igbesi aye ibẹrẹ ati iṣẹ iṣelu
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]A bi Jude Ngajile ni ọdun 1974 o si wa làti Ìpínlẹ̀ Cross River . Ni ọdun 2022, o jawe olubori nínú ibo abọ gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ to n ṣoju àgbègbè Ogoja/Yala ni ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà ni orílè-èdè Nàìjíríà lábé ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress (APC), lẹ́yìn ti o bori alátakò re Mike Usibe ti Peoples Democratic Party (PDP). [3]