Junior Lokosa
| Personal information | |||
|---|---|---|---|
| Orúkọ | Junior Sewanu Lokosa | ||
| Ọjọ́ ìbí | 23 Oṣù Kẹjọ 1993 | ||
| Ibi ọjọ́ibí | Badagry, Nigeria | ||
| Playing position | Centre-forward | ||
| Club information | |||
| Current club | Sporting Lagos F.C | ||
| Number | 18 | ||
| Senior career* | |||
| Years | Team | Apps† | (Gls)† |
| 2013–2018 | First Bank | 128 | (92) |
| 2018–2019 | Kano Pillars | 35 | (26) |
| 2019–2020 | ES Tunis | 11 | (6) |
| 2021 | Simba Sports Club | ||
| 2021–2022 | Kwara United F.C. | ||
| 2022–2023 | Al-Rayyan | ||
| 2023– | Sporting Lagos F.C | ||
| National team‡ | |||
| 2018– | Nigeria | 1 | (0) |
| * Senior club appearances and goals counted for the domestic league only and correct as of 15:04, 15 January 2019 (UTC). † Appearances (Goals). | |||
Junior Sewanu Lokosa (tí a bí ní ọjọ́ kẹtàlélógún oṣù kẹjọ ọdún 1993) jẹ́ agbábọ́ọ̀lù ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó ń gbá bọ́ọ̀lù fún ikọ̀ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Sporting Lagos FC.
Iṣẹ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Lokosa gbá bọ́ọ̀lù fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù First Bank kí ó to lọ parapò mo ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Kano Pillars ní oṣù karùn-ún ọdún 2017.[1] Ó gba bọ́ọ̀lù márùn-ún nínú ìdíje líìgì mẹ́rìnlá títí di òpin ṣáá ọdún 2017.[2]
Nígbà tí ó fi máa di àárín ṣáá ọdún 2018, Lokosa ti gba góólù mẹ́rìnlá nínú ìdíje mẹ́ẹ̀ẹ́dógún.[3] Ní oṣù karùn-ún ọdún 2018, ó lọ ṣe ìdánwò pẹ̀lú ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Ludogorets ti orílè-èdè Bulgaria, ó sì tún ṣe ìdánwò pẹ̀lú ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Brann tí orílè-èdè Norway.[4][5] Ní ìparí ṣáá náà, ó gba ẹ̀bùn Eunisell Boot Award lẹ́yìn tí góólù mẹ́rìndínlógún rẹ̀ mú un wà ní ipò àkọ́kọ́ nínú àtẹ àmì-ẹ̀yẹ NPFL, èyí tí ó fún un ní N3.8 mílíọ̀nù (N200,000 fún góólù kọ̀ọ̀kan).[6]
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Kano Pillars sign Nwagua Nyima, Lokosa". Sportinglens.blogspot.com. 14 May 2017.
- ↑ Dudu, Dammy (6 September 2017). "Lokosa Junior thrilled to form a formidable strike force with Nyima for Pillars". Sportlens360. Archived from the original on 15 May 2018. Retrieved 15 January 2018.
- ↑ "Junior Lokosa: What's the secret behind the NPFL hitman's scoring streak?". Goal. 26 April 2018.
- ↑ "CLOSE-UP: From Ajegunle to Bulgaria — Who Is Junior Lokosa, The Surprise Name On Nigeria's World Cup List?". Sahara Reporters (New York City, United States). 15 May 2018. http://saharareporters.com/2018/05/15/close-ajegunle-bulgaria-%E2%80%94-who-junior-lokosa-surprise-name-nigeria%E2%80%99s-world-cup-list. Retrieved 15 January 2019.
- ↑ "Junior Lokosa returns to Kano Pillars after failed Norway trails". Goal. 8 August 2018. Retrieved 15 January 2019.
- ↑ Agwubilo, Onyinyechukwu (9 November 2018). "Lokosa wins maiden Eunisell NPFL Boot Award, N3.8m". The Guardian (Lagos, Nigeria). https://guardian.ng/sport/lokosa-wins-maiden-eunisell-npfl-boot-award-n3-8m/. Retrieved 15 January 2019.